Browsing Category
Uncategorized
Sunday Igboho:Ilé-ẹjọ́ gíga ti ìjọba àpapọ̀ fàáké kọ́rí láti sègbẹ́jọ́ àwọn afurasí tí…
Ilé-ẹjọ́ gíga ti ìjọba àpapọ̀, tí a mọ̀ si Federal High Court tó wà nílùú Abuja , ni wọn ti fàáké kọ́rí láti sègbẹ́jọ́ àwọn afurasí mẹtala tí wọ́n kó nílé Sunday Igboho ni ọjọ kinni osu keje, nítorí ọdún iléyá.…
Ẹgbẹ́ òsèlú PDP nilẹ Gusu: Makinde tẹ́wọ́gba àbájáde ìgbìmọ̀ ẹlẹ́nu márùn ún
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde, ti tẹwọgba abajade igbimọ ẹlẹnu marun un ti gomina tẹlẹri fun ipinlẹ Ọsun ,Olagunsoye Oyinlola dari rẹ, lati yanju wahala ati isoro to n koju ẹgbẹ oselu, People’s Democratic Party (PDP) ni ila Gusu orilẹ…
Ilé ìgbìmọ̀ asòfin Nàíjíríà àti Ghana yóò fọwọ́sowọ́pọ̀ lórí ètò òfin ọrọ̀ ajé
ilé ìgbìmọ̀ asojú -sòfin orílẹ̀ èdè Nàíjíríà àti orílẹ̀ èdè Ghana ti fẹnukò lórí òfin tí ilé ìgbìmọ̀ asojú -sòfin méjéèjì yóò máa lò láti leè tẹpẹlẹ mọ́ ìbásepọ̀ àwọn méjéèjì pàápàá jùlọ…
A ó túbọ̀ fẹsẹ̀ ètò ìjọba tiwa-n-tiwa múlẹ̀ ní ẹkùn wa- Àjọ ilẹ̀ ECOWAS
Àjọ ilẹ̀ Afirika tí a mọ̀ sí, Economic Community of West African States, (ECOWAS) ti fẹnukò láti rí i pé wọ́n fẹsẹ̀ ètò ìjọba tiwa-n-tiwa múlẹ̀ ní ẹkùn wọn nípa gbígbárùkù ti ètò ìdìbò tó múná dóko ní ẹkùn…
Ẹ mú ètò ìwòsàn àwọn ọmọ ogun Nàíjíríà ní ọ̀kúnkúndùn-Ahmad Lawan
Abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asòfin lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà, Ahmad Lawan ti rọ àwọn adarí ilé-isẹ́ ọmọ ogun orílẹ̀ èdè yìí láti mú ètò ìwòsàn àwọn ọmọ ogun orílẹ̀ èdè yìí ní ọ̀kúnkúndùn, kí wọ́n sì sàtúnse…
Nàíjíríà ń sàjọyọ̀ ayẹyẹ odún ìjọba tiwa-n-tiwa nínú wàhálà òsèlú àti ọrọ̀ ajé…
Abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asòfin lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà, Ahmad Lawan ti ní ó seni láàánú pé nínú wàhálà àti ìpèníjà òsèlú àti ọrọ̀ ajé ni orílẹ̀ èdè Nàíjíríà ti ń se ayẹyẹ ọdún ìjọba tiwa-n- tiwa ti…
ìsẹ́ àti àínísẹ́ ló ń fa wàhálà lórí ètò ààbò- Buhari
Ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, Muhammadu Buhari ti ní ìjọba òun ti se gudugudu méje , yàyà mẹ́fa láàrin ọdún mẹ́fà tí wọn ti wà lórí àlèéfà láti ṣe àtúnse tó gbóúnjẹ fẹ́gbẹ́, gbàwo bọ̀ lórí ètò ọrọ̀ ajé.…
Ẹ máa sàánú àwọn olè, ajínigbé,ọ̀daràn, ẹ ṣe wọ́n bí ọsẹ se ń sojú-Buhari
Ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, Muhammadu Buhari, ti pàsẹ fún gbogbo àwọn ilé-isẹ́ agbófinró àti ilé-isẹ́ ọmọ ogun orílẹ̀ èdè yìí láti máa sàánú àwọn olè, ajínigbé ọ̀daràn àti àwọn tí wọ́n ń da omi…
Àwọn ènìyàn tó lé ní ẹgbẹ̀rún mẹ́rìndínlógún ni sìgá mímu ti gbẹ̀mí wọn ní…
Mínísítà fún ètò ìlera lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà,Osagie Ehanire ti kéde pé àwọn ènìyàn tí iye wọ́n lé ní́ ẹgbẹ̀rún mẹ́rìndínlógún ni sìgá mí́mu ti gbẹ̀mí wọn n lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà .Ó tẹ̀síwájú…
Wọ́ ti rí òkú àwọn ènìyàn mẹ́rìndínlọ́gọ́rin tó pàdánù ẹ̀mí wọn nínú ọkọ̀ ojú omi…
Gomina ipinlẹ Kebbi ti ní wọ́n ti rí òkú àwọn ènìyàn mẹ́rìndínlọ́gọ́rin tó padanu ẹmi wọn ninu ọkọ̀ ojú omi tó dànù ní Kebbi.
Atiku Bagudu tun tẹsiwaju pe ijọba oun yoo seto atunse ofin ti yoo fi ilana ti awọn awakọ oju…