ÌRÒYÌN YÀJÓ-YÀJÓ
- Ọlópàá Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Tú Ẹgbẹ́ Oníṣòwò Ọta Ìbọn Ká, Wọ́n Gba Ọta Ìbọn 2,625 Padà.
- Ààrẹ Tinubu Fi Àwọn Ìlànà Tuntun Sílẹ̀ Láti Kojú Ẹ̀tọ̀ Ààbò Ti Kó Péye To Ní Ìpínlẹ̀ Bauchi
- Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Ṣèlérí Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ Tó Dán Mọ́rán Pẹ̀lú Àwọn Ilé Iṣẹ́ Ìròyìn
- Ààrẹ Bínú Sí Àwọn Àlátakò Si òfin ìdìbò ọdún 2026.
- Igbákejì Ààrẹ Shettima Fọwọ́ Ṣí Àkójọpọ̀ Ìgbìmọ̀ Àwọn Oníròyìn Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà
- Ìlú Abuja: Ilé-iṣẹ́ Afẹ́fẹ́ Ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ṣe ìfilọ́lẹ̀ Ile-iṣẹ Wọn Tuntun
- Gomina Adamawa Ahmadu Fintiri Fi Ẹgbẹ́ Òṣèlú PDP silẹ fun Ẹgbẹ́ Òṣèlú APC.
- Àdéhùn: Ilé ìgbìmọ̀ Aṣòfin Pè Fún Sí San Owó Bi Ti Àtẹhìnwá.
- Ìpínlẹ̀ Kaduna: Ẹgbẹ́ Ń Bá Àjọ UNICEF Ṣiṣẹ́ Lórí Ìlera, Ààbò Àwọn Ọmọdé
- Ètò Isuna Ọdún 2026: Mínísítà Fún Ẹ̀tọ̀ Ẹ̀kọ́ Bẹrẹ Fún Àfikún Owó Lórí Ètò Ẹ̀kọ́.
ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ
Ààrẹ orílẹ̀-èdè US Trump yin Ọjọ́ Orí Àwọn Àgbàlagbà ní Ìpínlẹ̀ Àwọn Orílẹ̀-èdè Naa
Ààrẹ Amẹ́ríkà Donald Trump fọ́nnu nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ ní ọjọ́ Ìṣẹ́gun pé òun ti mú “àkókò wúrà ti Amẹ́ríkà” wá, ó ń wá…
Awọn Abáni jẹ Láti Orílẹ̀-èdè Ukraine Ni Alatako Lati Tun Mi Yan: Hungary Orban
Ní dídojúkọ àwọn ìṣòro líle koko nínú ìdìbò tí ń bọ̀, olórí ìjọba Hungary tí ó ń gbèjà Orílẹ̀-èdè Russia ń…
Àwọn Tọrọ Kan Gboriyin Fún Pínpín Ọkọ Katakata Fún Àwọn Àgbẹ̀
Ilé Ìfowopamọ́ fún àwọn àgbẹ̀ (BOA) àti àwọn tọrọ kan mìíràn ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti gbóríyìn fún pípín àwọn…
Korea Múlele Jîjinlẹ̀ Ẹ̀kọ́ Pàṣípáàrọ̀ Àṣà Pẹ̀lú Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà
Olùdarí Ilé-iṣẹ́ Àṣà Korea ní Nigeria (KCCN), Ọ̀gbẹ́ni Jeon Ju-ho, sọ pé ilé-iṣẹ́ náà ti ṣètò àwọn ètò…
ÌRÒYÌN ÀṢÀ ÀTI ÌṢE YORÙBÁ
Ọ̀nà Àbáyọ Si Ìdájọ Òdodo Àti Ìpẹ̀tù Sí Aáwọ̀: Aláàfin Ọ̀yọ́ Pé Fún Ìbáṣepọ̀…
Aláàfin Ìlú Ọ̀yọ́, Ọba Akeem Abímbólá Owoade I ti tẹnu mọ́ pé òun dúró digbí lórí èrò rere tí òun ni fún àwọn…
ÌRÒYÌN ORÍLẸ̀-ÈDÈ NÀÍJIRÍÀ
Ọlópàá Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Tú Ẹgbẹ́ Oníṣòwò Ọta Ìbọn Ká, Wọ́n Gba Ọta Ìbọn 2,625 Padà.
Ni ìbámu pẹ̀lú ìpinnu ilé iṣẹ́ Ọlọ́pàá Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ láti dẹkùn ìwà ìdigunjalè ni Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ati àwọn agbègbè to…
ÌRÒYÌN ÁFÍRÍKÀ
Ilé Iṣẹ́ ijọba Ìṣòwò Gúúsù Áfíríkà lòdì Sí Ìtújáde ìpèsè Sugar
Ilé Iṣẹ́ ìjọba Ìṣòwò Gúúsù Áfíríkà sọ ní ọjọ́ Ẹtì wí pé òun yóò tako ìtújáde àwọn olùpèsè suga Tongaat Hulett…
ÌRÒYÌN ÒSÈLÚ
Gomina Adamawa Ahmadu Fintiri Fi Ẹgbẹ́ Òṣèlú PDP silẹ fun Ẹgbẹ́ Òṣèlú APC.
Gomina Ipinle Adamawa Ahmadu Fintiri ti fi egbe Peoples Democratic Party (PDP) silẹ ni ifowosi o si darapo mo egbe All Progressives Congress (APC), o si so ìpínlẹ̀ náà pọ mọ ẹgbẹ́ to n se ijoba lọ́wọ́
Gomina fi ẹgbẹ́ náà sile pẹ̀lú àwọn…
Sẹ́nétọ̀ Dickson Gba Ẹ̀bùn Ami Ẹyẹ Atọ́nisọ́nà Tó Dájú
Sẹ́nétọ̀ Seriake Dickson, tó ń ṣojú fún ìwọ̀ oòrùn Bayelsa ní ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, ti gba ẹ̀bùn ìtọ́sọ́nà tó dájú fún ipa ribiribi rẹ̀ fún àwọn ènìyàn àti àwùjọ lápapọ̀.
Àjọṣepọ̀ àwọn àjọ Civil Society…
Ẹgbẹ́ APC Ìpínlẹ̀ Kwara Fọwọ́sí Àwọn Olórí Ẹgbẹ́ Tuntun
Àwọn Olórí ẹgbẹ́ òṣèlú 'All Progressives Congress APC' ti Ìpínlẹ̀ Kwara ní ọjọ́ Àbámẹ́ta, tún gbá àṣẹ láti tẹ̀síwájú ṣe olórí jákèjádò Ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́rindínlógún pẹ̀lú ìfọwọ́sowọ́pọ̀ gbogbo ọmọ ẹgbẹ́.
Ìgbésẹ̀ náà, èyítí o fa àwọn…
Gómìnà Kano Gbóríyìn Fún INEC Àti Àwon Ilé-iṣẹ́ Ààbò Fún Ìdìbò Àlàáfíà
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kano, Abba Yusuf, ti yín Ìgbìmọ̀ Elétò Ìdìbò Olómìnira Orílẹ̀-èdè (INEC), àti àwọn ilé-iṣẹ́ ààbò fún iṣẹ́ àlàáfíà àti ìlànà tí ìdìbò abẹ́lé ní Ìpínlẹ̀ náà.
Ìyìn Gómìnà náà ní a gbé jáde nínú àtẹ̀jáde kán tí agbẹnusọ…
ÌRÒYÌN ÌDÁNILÁRAYÁ
Òṣèrébìnrin Ará Bìrìtikó Pẹ̀lú Nàìjíríà, Wunmi Mosaku Gba Ẹ̀bùn Ẹ̀yẹ BAFTA Tó Dára…
Òṣèrébìnrin ará Bìrìtikó àti Nàìjíríà, Wunmi Mosaku, ti gba ẹ̀bùn ẹyẹ BAFTA fún òṣèrébìnrin tó dára jùlọ…
ÌRÒYÌN ÌLERA
Ẹgbẹ́ EHCON Ṣe ìfilọ́lẹ̀ Ẹ̀tọ̀ Ìdínkù Gáàsì .
Igbimọ Ilera Ayika ti Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà (EHCON) ti ṣe ifilọlẹ Eto Idinku Awọn Egbin Gaasi Ile-ọfin ti mu didara…
Àjọ FCTA Pèsè Ìṣedúró Ìlera Ọ̀fẹ́ Fun Àwọn Oníròyìn
Akowe Ofin ti ilu Abuja fún ètò ìlera àti agbègbè (FCTA) , Dokita Adedolapo Fasawe ti fọwọsi iforukọsilẹ iṣeduro…