ÌRÒYÌN YÀJÓ-YÀJÓ
- Sẹ́nétọ̀ Dickson Gba Ẹ̀bùn Ami Ẹyẹ Atọ́nisọ́nà Tó Dájú
- Àjọ NigComSat Fọwọ́ Sí Iwé Àdéhùn Pẹ̀lú Uniccon Láti Mú Kí Iṣẹ́ Ìtọ́jú Ìlera Sunwọ̀n Síi
- Òṣèrébìnrin Ará Bìrìtikó Pẹ̀lú Nàìjíríà, Wunmi Mosaku Gba Ẹ̀bùn Ẹ̀yẹ BAFTA Tó Dára Jùlọ Fún Ti Àwọn Òṣèrébìnrin
- Ààrẹ Tinubu Gba Àwọn Gómìnà Lálejò Ní Àkókò Ìtùnú Aawẹ̀ Ramadan
- Aya Ààrẹ Gbóríyìn fún Àjọ UNICEF fún Gbígbé Ìforúkọsílẹ̀ Ọjọ́ Ìbí Ọmọ Nàìjíríà Lårugẹ
- Ìpínlẹ̀ Cross River: Àwọn ọlọ́pàá Ti Sẹ Àkọsílẹ̀ Ìdàgbàsókè Pàtàkì Ṣí Ẹgbẹ́ Ìṣòwò Ọjà.
- Àjọ WFP Pé Ìpè pajawiri Lati Mu Àtìlẹ́yìn Óunjẹ Dúró Ní Somalia.
- Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Gba Owó Ìbẹ̀rẹ̀ Àádọta Mílíọ̀nù Dọ́là$ Nípasẹ̀ Ìbáṣepọ̀ NSIA–JICA
- Aṣojú Ìṣúra Orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà Ṣè Àbẹ̀wò sí Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà
- Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà fún Àwọn olùfowópamọ́ Kẹ́rẹ́je Ni Ààbò òfin.
ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ
Àwọn Tọrọ Kan Gboriyin Fún Pínpín Ọkọ Katakata Fún Àwọn Àgbẹ̀
Ilé Ìfowopamọ́ fún àwọn àgbẹ̀ (BOA) àti àwọn tọrọ kan mìíràn ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti gbóríyìn fún pípín àwọn…
Korea Múlele Jîjinlẹ̀ Ẹ̀kọ́ Pàṣípáàrọ̀ Àṣà Pẹ̀lú Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà
Olùdarí Ilé-iṣẹ́ Àṣà Korea ní Nigeria (KCCN), Ọ̀gbẹ́ni Jeon Ju-ho, sọ pé ilé-iṣẹ́ náà ti ṣètò àwọn ètò…
Akọrin Ìgbàgbọ́ Ọmọ Amẹ́ríkà Papòdà Ní Ẹni Ọ̀kànlélọ́gọ̀rin Ọdún
Gbajúmọ̀ akọrin ìgbàgbọ́ ọmọ ilẹ̀ Amẹ́ríkà, adari ìyìn àti olùṣọ àgùntàn, Ron Kenoly ti papòdà ní ẹni…
Orílẹ-èdè Tunisia: Àwọn Àdọ́ọ́ta Ènìyàn Ló Pàdánù Èmí Wọn Nínú Ìjàmbá Ọkọ̀ Ojú Omi Tó…
Ènìyàn kan péré ni Ọlọrun gbà Emi re là nínú ìjàmbá ọkọ̀ ojú omi ti o sẹlẹ̀, ti àwọn àdọ́ọ́ta sí pàdánù èmí wọn…
ÌRÒYÌN ÀṢÀ ÀTI ÌṢE YORÙBÁ
Ọ̀nà Àbáyọ Si Ìdájọ Òdodo Àti Ìpẹ̀tù Sí Aáwọ̀: Aláàfin Ọ̀yọ́ Pé Fún Ìbáṣepọ̀…
Aláàfin Ìlú Ọ̀yọ́, Ọba Akeem Abímbólá Owoade I ti tẹnu mọ́ pé òun dúró digbí lórí èrò rere tí òun ni fún àwọn…
ÌRÒYÌN ORÍLẸ̀-ÈDÈ NÀÍJIRÍÀ
Sẹ́nétọ̀ Dickson Gba Ẹ̀bùn Ami Ẹyẹ Atọ́nisọ́nà Tó Dájú
Sẹ́nétọ̀ Seriake Dickson, tó ń ṣojú fún ìwọ̀ oòrùn Bayelsa ní ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, ti…
ÌRÒYÌN ÁFÍRÍKÀ
Ilé Iṣẹ́ ijọba Ìṣòwò Gúúsù Áfíríkà lòdì Sí Ìtújáde ìpèsè Sugar
Ilé Iṣẹ́ ìjọba Ìṣòwò Gúúsù Áfíríkà sọ ní ọjọ́ Ẹtì wí pé òun yóò tako ìtújáde àwọn olùpèsè suga Tongaat Hulett…
ÌRÒYÌN ÒSÈLÚ
Sẹ́nétọ̀ Dickson Gba Ẹ̀bùn Ami Ẹyẹ Atọ́nisọ́nà Tó Dájú
Sẹ́nétọ̀ Seriake Dickson, tó ń ṣojú fún ìwọ̀ oòrùn Bayelsa ní ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, ti gba ẹ̀bùn ìtọ́sọ́nà tó dájú fún ipa ribiribi rẹ̀ fún àwọn ènìyàn àti àwùjọ lápapọ̀.
Àjọṣepọ̀ àwọn àjọ Civil Society…
Ẹgbẹ́ APC Ìpínlẹ̀ Kwara Fọwọ́sí Àwọn Olórí Ẹgbẹ́ Tuntun
Àwọn Olórí ẹgbẹ́ òṣèlú 'All Progressives Congress APC' ti Ìpínlẹ̀ Kwara ní ọjọ́ Àbámẹ́ta, tún gbá àṣẹ láti tẹ̀síwájú ṣe olórí jákèjádò Ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́rindínlógún pẹ̀lú ìfọwọ́sowọ́pọ̀ gbogbo ọmọ ẹgbẹ́.
Ìgbésẹ̀ náà, èyítí o fa àwọn…
Gómìnà Kano Gbóríyìn Fún INEC Àti Àwon Ilé-iṣẹ́ Ààbò Fún Ìdìbò Àlàáfíà
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kano, Abba Yusuf, ti yín Ìgbìmọ̀ Elétò Ìdìbò Olómìnira Orílẹ̀-èdè (INEC), àti àwọn ilé-iṣẹ́ ààbò fún iṣẹ́ àlàáfíà àti ìlànà tí ìdìbò abẹ́lé ní Ìpínlẹ̀ náà.
Ìyìn Gómìnà náà ní a gbé jáde nínú àtẹ̀jáde kán tí agbẹnusọ…
Wike Gbóríyìn Fún Ìdìbò Àlàáfíà Àti Ìwà Àwọn Olùdìbò
Mínísítà fún Agbègbè Olú-ìlú Nàìjíríà (FCT), Nyesom Wike, ti ṣàpèjúwe ìdìbò tí agbègbè Olú-ìlú Nàìjíríà gẹ́gẹ́ bí “àlàáfíà” ó sì gbóríyìn fún àwọn olùdìbò fún ìwà àlàáfíà.
Mínísítà náà gbóríyìn fún wọn lẹ́yìn tó ṣe àkíyèsí ìdìbò náà…
ÌRÒYÌN ÌDÁNILÁRAYÁ
Òṣèrébìnrin Ará Bìrìtikó Pẹ̀lú Nàìjíríà, Wunmi Mosaku Gba Ẹ̀bùn Ẹ̀yẹ BAFTA Tó Dára…
Òṣèrébìnrin ará Bìrìtikó àti Nàìjíríà, Wunmi Mosaku, ti gba ẹ̀bùn ẹyẹ BAFTA fún òṣèrébìnrin tó dára jùlọ…
ÌRÒYÌN ÌLERA
Ìpínlẹ̀ Kano, Àjọ Pàtàkì Fún Ètò Imototo Ati Fifọ Ọwọ́ (WASH) Ṣe Àgbékalẹ̀ Ètò…
Wọ́n ti ṣe àgbékalẹ̀ àǹfààní sí àwọn iṣẹ́ omi, ìmọ́tótó ní àwọn apá kan ní Ìpínlẹ̀ Kano lẹ́yìn àwọn ìtọ́jú tí ó…
Báńkì fún Iṣẹ́ Àgbẹ̀ Gbóríyìn fún Ìgbìyànjú Ìyàwó Àkọ́kọ́ Lórí Oúnjẹ Tí Kò Péye
Olùdarí Àgbà fún Báńkì fún Iṣẹ́ Àgbẹ̀, Ayo Sotinrin ti gbóríyìn fún àwọn ètò iṣẹ́ àgbẹ̀ àti oúnjẹ tí Ìyàwó Àkọ́kọ́…