ÌRÒYÌN YÀJÓ-YÀJÓ
- Asiwaju Bola Ahmed Tinubu Ló Lè Ṣe Àkóso Orílẹ̀ Èdè Nàìjíríà Láì Fi Ti Ẹ̀sìn Tàbí Ẹ̀yà Ṣe: Alhaji Abduljelili Adesiyan
- Orìlẹ̀-èdè Nàìjíríà Bá Orilẹ́-èdè Turkey Àti Syria Kẹ́dùn Látàrí Ìjàmbá Ilé Mímì To Ṣẹlẹ̀ Ní Orílẹ̀-èdè Méjèjì.
- Orílẹ̀-èdè Ethiopia Ti Ya Àádọ́rin mílíọ̀nù Dọ́là Sọ Tọ̀ Láti Fi Bẹ̀rẹ Òkòwò Ilé Ifowopamọ Sí.
- NI Orílẹ̀-èdè Chile: Enìyàn Mẹ́tàlá Ló Pàdánù Ẹ̀mi Wọn Nínú Ìjàmbá Ìna.
- Àǹfàání Tó Pọ̀ Lo Wà Nínú Ẹ̀kọ Fún Ìgbega Ìlú: Gómìnà ìpínlẹ̀ Katsina.
- Inú Mi Kò Dun Bi Wọn Ṣe Pa Àwọn Ọmọ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ní Orílẹ̀-èdè Burkina Faso.: Ààrẹ Buhari
- Ìjọba Ìpínlẹ̀ Anambra Fọ́wọ́ Sọya Láti Dẹkùn ọ̀wọn Gógò Epo Ní Ìpínlẹ̀ Náà.
- Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Yóò Tún Ìpàdé Ṣe Ti Ilé Ìfowòpamọ́ Àpapọ Ba Kùnà Lati Wa Ojútùú Sí Rògbòdìyàn Owó Tuntun Àti Owó Àtijọ Orílẹ-èdè Nàìjíríà.
- Ilé Aṣòfin Èkó pè fún sisun gbèdéke níná owó náírà tẹ́lẹ̀ di oṣù keje ọdún
- Kóní kálukú yín sagbéjẹ́ mọ́wọ́
ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ
Orílẹ̀-èdè Ethiopia Ti Ya Àádọ́rin mílíọ̀nù Dọ́là Sọ Tọ̀ Láti Fi Bẹ̀rẹ Òkòwò Ilé…
Ìjọba orílẹ̀-èdè Ethiopia ní òhun tí ya Àádọ̀rún mílíọ̀nù Dọ́là ṣọ́ tọ̀ láti fí bẹ̀rẹ okówó ilé ìfowópamọ́ sí ní…
NI Orílẹ̀-èdè Chile: Enìyàn Mẹ́tàlá Ló Pàdánù Ẹ̀mi Wọn Nínú Ìjàmbá Ìna.
Ìjàmbá iná tó ṣe yọ ni orílẹ̀-èdè Chile lo ti gbà ẹ̀mí àwọn ènìyàn mẹ́tàlá, tí ó sí bá àwọn ilé tó tó…
Ọgọ́rùn ún Ènìyàn Ti Gbèkuru Jẹ Lọ́wọ́ Ẹbọra Nínú Ìṣẹ̀lẹ̀ Àdó Olóró Tó Bú Gbámù Ní…
Ọgọrùn Ènìyàn ló ti gbẹ̀mí mì nínú ìṣẹ̀lẹ̀ ìkọlù àti ìgbẹ̀mí ara ẹni pẹ̀lú àdó olóró ní Mọ́sálásí kan ní…
A Kò Sàtìlẹyìn Kíkó Ohun Ìjà Fún Russia- Orílẹ̀ Èdè North Korea Fi Ọ̀rọ̀…
Orílẹ̀ èdè North Korea ti sọ wípé òun kò kópa nínúu ṣíṣe àtìlẹyìn nǹkan ogun fún orílẹ̀ èdè…
ÌRÒYÌN ÀṢÀ ÀTI ÌṢE YORÙBÁ
Ona TI Abaji,Alhaji Adamu Baba Yunusa sayẹyẹ ọdún márùndínlọ́gbọ̀n lórí…
Ona of Abaji , to tun jẹ alaga igbimọ awọn lọba-lọba niluu Abuj,FCT ,His Royal Majesty (HRM) Alhaji Adamu Baba…
ÌRÒYÌN ORÍLẸ̀-ÈDÈ NÀÍJIRÍÀ
Asiwaju Bola Ahmed Tinubu Ló Lè Ṣe Àkóso Orílẹ̀ Èdè Nàìjíríà Láì Fi Ti Ẹ̀sìn Tàbí…
Alága Ìgbìmò ìdìbò abẹle fún ẹgbẹ́ òṣèlú APC ni Ìpínlè Ọ̀yọ́, Alhaji AbdulJelili Adesiyan, tí o ti fi igba kan ri…
ÌRÒYÌN ÁFÍRÍKÀ
Kóní kálukú yín sagbéjẹ́ mọ́wọ́
Àwọn adarí agbègbè ti pè fún ìdádúró ìjà láàrin gbogbo àwọn ẹgbẹ́ ní Ilà oòrùn Democratic…
ÌRÒYÌN ÒSÈLÚ
Ìdìbò 2023: Ẹ dáábòbò ìbò yín o
Àlùfáà Johnson Suleman, gbajúgbajà ìránṣẹ́ ọlọ́run tí ó jẹ́ ọmọ Nàìjíríà,tí ó tún jẹ́ ààrẹ ìjọ Omega Fire, ti gba àwọn ọmọ Nàìjíríà nímọ̀ràn pé kí wọ́n dábòbò ìbò wọn lásìkò ìdìbò gbogbogbòò.…
Ìdìbò 2023 : A ti gbaradì fún ìpèsè ààbò Bauchi/Gombe – AIG
Igbákejì ọ̀gá àgbà àwọn agbófinró tuntun, AIG tí ó ń ṣàkóso agbègbè kejìlá,tí ó jẹ́ ìpínlẹ̀ Bauchi àti Gombe, Ọ̀gbẹ́ni Ọláwálé Taoheed Olókodé, ti fi dá àwọn ènìyàn agbègbè náà lójú pé àwọn ti…
INEC kò ní já àwọn ọmọ Nàìjíríà kulẹ̀ nínú ìdìbò gbogbogbòò 2023 – REC
Ọ̀jọ̀gbọ́n Ayòbámi Sàlámì, alábojútó ètò ìdìbò ní ìpínlẹ̀ Èkìtì,(REC) ti ìgbìmọ̀ olómìnira tó ń mójútó ètò ìdìbò lápapọ̀, (INEC) ti sọ pé,ìgbìmọ̀ náà kò ní já àwọn ọmọ Nàìjíríà kulẹ̀ nínú…
Ètò Ìdìbò: BVAS Yóò Rán Àwọn Ọmọ Orílẹ̀-èdè Yí Lọ́wọ́ Látí Yàn Olórí Tí Wọ́n Fẹ́ Sípò – DG VON
Olùdarí Àgbà tí Voice of Nigeria, VON, Osita Okechukwu sọ pé pèlú ìfilọ́lẹ̀ ètò ìforúkọsílẹ àwọn olúdìbò (Bimodal Voters Accreditation System) BVAS, àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà yóò yàn olubori nínù ètò ìdìbò gbogbogbò 2023.
DG sọ èyí…
ÌRÒYÌN ÌDÁNILÁRAYÁ
Oǹkọrin Ọmọ Nàìjíríà Gbé Àwo Orin Tuntun Jáde Tó Pe Àkọ́lé Rẹ̀ Ní ‘Stand By You.’
Oǹkọrin omọ Naijiria ti gbé àwo orin tuntun jade to pe akole re ni - 'Dúró timi‘. Eléyìí mú kí inú àwọn…
ÌRÒYÌN ÌLERA
Àjọ Adójútòfò Pèsè Ohun Èlò Ìlera Fún Àwọn Ilé Ìwòsàn Ní…
Kò dín ní Ilé ìwòsàn mẹ́ẹ̀rin ní ìpínlẹ̀ Kano tí ó ti jẹ ànfààní ìpèsè àwọn ohun èlò…
Aya Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kebbi Pè Fún Pípèsè Ohun Èlò Tí Ó Péye Fún…
Arábìnrín àkọ́kọ́ ní ìpínlẹ̀ Kẹbbi, Ọ̀mọ̀wé Zainab Shinkafi Bagugu ti ké sí àwọn aládàníi àti Ìjọba…