ÌRÒYÌN YÀJÓ-YÀJÓ
- Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Fọwọ́ Sí Owó Tó Lé Ní Ọgọ́jọ Bílíonì Naira Fún Àtúnse Òpópónà
- Ààrẹ Buhari Yóò Lọ Kí Ààrẹ UAE Titun
- Ilẹ́-Isẹ́ Ọlọ́ọ̀pá Yóò Lọ Ìmọ̀ Ẹ̀ro Láti Kọjú Ìwà Ọ̀danràn
- Nàìjíríà le jẹ́kan lára àwọn orílẹ̀-èdè tó dára jù lọ – Ọ̀sínbàjò
- Àpèjọ Àgbáyé Lórí Ìgbógunti fífọmọ ṣòwò ẹrú bẹ̀rẹ̀ Ní South Africa
- Ìdùnnú ṣubú layọ̀ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ́lù Flying Eagles
- ASUP:Ilé-èkọ́ gíga iṣẹ́ ọwọ́ Násáráwá Darapọ̀ mọ́ ìyanṣẹlódì gbogbogbòò
- Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó Pè fún ìrọ̀wọ́ rọsẹ̀ ìdìbò alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ egbẹ́ APC
- NMA banújẹ́ Lórí Ètò Ìtọ́jú Ìlera Alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ tó mẹ́hẹ
- Gómìnà ìpínlẹ̀ Kano tẹ́lẹ̀ rí, Shekaráú, Fi APC sílẹ̀, Ó Darapọ̀ mọ́ NNPP
ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ
Liverpool fa aṣọ iyì Chelsea ya nígbà tí wọ́n jáwé olúborí nínú ìdíje FA CUP
Ẹgbẹ́ agbábọ̀ọ̀lù Chelsea bá Liverpool fa kàngbọ̀n lóri pápá, nígbàtí kò sí ẹni tó mi àwọ̀n nínú…
Ààrẹ Buhari kí Olórí orílẹ̀-èdè UAE Tuntun kú oríre
Ààre Muhammadu Buhari kí Ààrẹ titun ti United Arab Emirates, Sheikh Mohamed bin Zayed, tí ó jẹ Ààrẹ ìjọba…
Àwọn Olórí orílẹ̀-èdè Nàíjiríà Ṣọ̀fọ̀ Ikú Ààrẹ UAE, Late Sheikh Khalifa
Ààrẹ Muhammadu Buhari sọ pé ikú Ààrẹ orílẹ̀-èdè United Arab Emirates (UAE) Sheikh Khalifa Bin Zayed Al Nahyan ti…
Àwọn Gómìnà orílẹ̀-èdè Russia mẹ́rin kọ̀wé fiṣẹ́ sílẹ̀ nítorí ìjẹníyà
Àwọn gómìnà agbègbè mẹ́rin ní orílẹ̀-èdè Russia ti fi ipò sílẹ̀ ní ọjọ́ Ìṣẹ́gun, bí orílẹ̀-èdè…
ÌRÒYÌN ÀṢÀ ÀTI ÌṢE YORÙBÁ
Asiwaju Bola Ahmed Tinubu fi Aláàfin Ọ̀yọ́ tó wàjà, Ọba Lamidi Adeyemi III wé…
Asiwaju Bola Tinubu ló sọ ọ̀rọ̀ yí di mímọ̀ ní àsìkò tí wọ́n ṣe ádùrá ọjọ́ kẹjọ ní ìrántí ìpapòdà Aláàfin Ọ̀yọ́,…
ÌRÒYÌN ORÍLẸ̀-ÈDÈ NÀÍJIRÍÀ
Nàìjíríà le jẹ́kan lára àwọn orílẹ̀-èdè tó dára jù lọ – Ọ̀sínbàjò
Igbákejì Ààrẹ Nàìjíríà, Ọ̀jọ̀gbọ́n Yẹmí Ọ̀sínbàjò sọ pé Nàìjíríà ní gbogbo ohun tí ó gbà…
ÌRÒYÌN ÁFÍRÍKÀ
Àpèjọ Àgbáyé Lórí Ìgbógunti fífọmọ ṣòwò ẹrú bẹ̀rẹ̀ Ní South Africa
Bí Àpèjọ Káríayé Karùn-ún lórí Ìgbógunti fífọmọ ṣòwò ẹrú ti bẹ̀rẹ̀ ní Durban,orílẹ̀-èdè South…
ÌRÒYÌN ÒSÈLÚ
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó Pè fún ìrọ̀wọ́ rọsẹ̀ ìdìbò alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ egbẹ́ APC
Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkó, Ọ̀gbẹ́ni Babajídé Sanwò-Olú, àti Ìgbìmọ̀ olùgbàmọ̀ràn ìjọba,GAC, ti ké sí àwọn aṣaájú àti àwọn ọmọ ẹgbẹ́ All Progressive Congress láti ṣe jẹ́jẹ́ lásìkò àwọn ìdìbò alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ àti…
Gómìnà ìpínlẹ̀ Kano tẹ́lẹ̀ rí, Shekaráú, Fi APC sílẹ̀, Ó Darapọ̀ mọ́ NNPP
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kano tẹ́lẹ̀ rí, Sẹ́nétọ̀ Ibrahim Shekarau, ti fi ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress, APC sílẹ̀,tí ó sì dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú New Nigeria Peoples Party, NNPP.
Oludari Agba fun ẹgbẹ to n ṣatilẹyin fun Asiwaju Bọla…
Ọ̀ṣun 2022: Ọ̀gọ̀ọ́rọ́ Àwọn Olólùfẹ́ PDP ń Yípadà sí APC Ní ìjọba ìbílẹ̀ Ayédáadé
Ipò ẹgbẹ́ òṣèlú alátakò pàtàkì nípínlẹ̀ Ọ̀sun, People’s Democratic Party, PDP, ti dín kù gan-an nígbà tí ó lé ní ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta lára àwọn ọmọ ẹgbẹ́ rẹ̀ ló ti kéde pé àwọn fẹ́ dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressive Congress, APC, ní…
Aṣojú ẹgbẹ́ APC ní ìpínlẹ̀ Kàdúná àti Niger Fòhùntẹ̀ lu Tinúubú
Àwọn aṣojú ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress ní ìpínlẹ̀ Kàdúná àti Niger ti fọwọ́sí èròńgbà fún ipò ààrẹ olóyè ẹgbẹ́, Asiwájú Bọ́lá Tinúubú.
Gẹgẹ bi atẹjade ti ile- iṣẹ ibaraẹnisọrọọ Tinubu gbe jade, awon…
ÌRÒYÌN ÌDÁNILÁRAYÁ
Big Brother Nàìjá ẹlẹ́ẹ̀keje bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹu
Big Brother Nàìjá ẹlẹ́ẹ̀keje bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹu.
Awọn oluṣeto idije naa,fihan ninu fidio gigun iṣẹju kan ti o…
ÌRÒYÌN ÌLERA
NMA banújẹ́ Lórí Ètò Ìtọ́jú Ìlera Alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ tó mẹ́hẹ
Ẹgbẹ́ Ìṣòògùn Nàìjíríà (NMA),ti banújẹ́ lórí Ètò Ìtọ́jú Ìlera Alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ tó mẹ́hẹ ní…
Ẹ máá fi ẹ̀tọ́ wa dùnwá
Awọn oṣiṣẹ eto ilera nipinlẹ Abia ni ana fi ẹhonu wọn han latari owo oṣu mejila wọn ti wọn ko san, ti won si n…