Browsing Category
ÌRÒYÌN ÒSÈLÚ
This is a category for politics news
Aiyedatiwa Jáwé Olúborí Gẹ́gẹ́ Bí Olùdíje Sí Ipò Gómìnà Níbí Ìdìbò Abẹ́lé Ẹgbẹ́…
Gómìnà Lucky Aiyedatiwa ti ìpínlẹ̀ Ondo ni wọ́n ti kéde gẹ́gẹ́ bí ẹni tí ó jáwé olúborí níbi ìdìbò abẹ́lé ẹgbẹ́ òsèlú APC láti yan olùdíje lábẹ́ àsìá ẹgbẹ́ náà fún ìdìbò sí ipò gómìnà tí yóò wáyé…
Ẹgbẹ́ Òsèlú APC Ti Gbáradì Fún Ìjáwé Olúborí Nínú Ìdíje Sí Ipò Gómìnà Tí Yóò…
Ẹgbẹ́ òsèlú APC ti ń là kààkà pẹ̀lú Ìgbìyànjú tí ó múná dóko láti ríi dájú pé ẹgbẹ́ náà jáwé́ olúborí nínú ìdíje sí ipò gómìnà èyí tí yóò wáyé ní ìpínlẹ̀ Edo
Àwọn olóyè ẹgbẹ́…
Ààbò Tí Ó Péye Yóò Wà Lásìkò Ìdìbò Ìjọba Ìbílẹ̀ Ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́- Àjọ…
Àjọ Ọlọ́pàá Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti fún àwọn olùgbé Ìpínlẹ̀ ní àrídájú láti má se fòyà àtipé ìdáàbòbò tí ó péye yóò wà fún ẹ̀mí àti dúkìá àwọn ará ìlú gẹ́gẹ́ bí àkókò ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ se ń…
Ìgbìmọ̀ Ẹgbẹ́ Òṣèlú PDP Ṣe Ìlérí Láti Jẹ Agbára Fún Ẹgbẹ́ Náà.
Ìgbìmọ̀ Ẹgbẹ́ Òṣèlú PDP ti ṣe ìlérí láti ṣiṣẹ takuntakun fún igbedide àti òkun fún ẹgbẹ́ òṣèlú PDP.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Bauchi tó tún jẹ Alága fún ìgbìmọ̀ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP Bala Mohammed lo sọ èyí di mímọ nígbà tí o n ba àwọn oníròyìn sọrọ…
Ààrẹ Tinúbú Sọ̀fọ̀ Ikú Ogbonnaya Onu
Ààrẹ Bola Tinubu sedaro pẹlu ẹbi Onu latari ipapoda Mínísítà tẹlẹ ri ti Sáyẹnsì, ìmọ ẹrọ ati ọgbọn tuntun, Oloye Ogbonnaya Onu, CON.
Olórí orílẹ̀-èdè gbosuba fún oloogbe náà pe Ọ̀mọ̀wé to làlùyọ ni, onipo kínní ninu iṣẹ ìmọ̀ ẹ̀rọ,…
Ọmọ Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Se Ìrànlọ́wọ́ Ohun Èlò Ọdún Fún Àwọn Ènìyàn Rẹ̀
Ọmọ Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin tí ó ń sojú ẹkùn Karu/Giata ní Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Ìpínlẹ̀ Nasarawa, Ọnọrébù Jonah Ali Dizaho pín ọ̀pọ̀lọpọ̀ owó àti Ìrẹsì fún àwọn ènìyàn tí ó ń sojú fún, ní papàá jùlọ àwọn…
Ọmọ Asòfin Pín Ohun Amáyédẹrùn Fún Àwọn Ènìyàn Ìpínlẹ̀ Nasarawa
Síwájú ayẹyẹ odún ìtúnu ààwẹ̀, ọmọ asòfin tí ń sojú ẹkùn Uke/ Karashi ní Ilé ìgbìmọ̀ Asòfin Ìpínlẹ̀ Nasarawa, Ọnọrébù Saidu Gude ti pín àpò ìrẹsì èyí tí ó le ní irinwó, asọ, owó, fún àwọn ènìyàn ẹkùn…
Adarí Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Ìpínlẹ̀ Nasarawa Pè Fún Wíwá Àforíjì Ẹ̀ṣẹ̀ Lásìkò…
Gẹ́gẹ́ bí àwọn onígbàgbọ́ jákè-jádò gbogbo àgbáyé se ń rántí ikú àti àjídìde Jesu, adarí Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Ìpínlẹ̀ Nasarawa, Ọnọrébù Danladi Jatau ti kí àwọn ọmọ lẹ́yìn Jesu kú oríire àyájọ́ pàtàkì…
Adarí Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Ìpínlẹ̀ Anambra Pè Fún Ìfẹ́ Lásìkò Àti Lẹ́yìn Àjí-ìn-de
Adarí Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Ìpínlẹ̀ Anambra, Ọ̀gbẹ́ni Somtochukwu Udeze ti rọ ọmọ Nàìjíríà papàá jùlọ àwọn ọmọ lẹ́yìn kírísítì láti tẹ̀lé ìlànà, ẹ̀kọ́, ìfẹ́, ìfarajì, àlàáfíà èyí́ tí ikú àti àjídìde…
Ọdún Àjíǹde: Ẹgbẹ́ Òsèlú APC Pè Fún Ìsọ̀kan, Àlàáfíà, Ìdúróṣinṣin Àti Ọrọ̀ Fún Nàìjíríà
Alága gbogbogbò Ẹgbẹ́ Òsèlú APC, Abdullahi Ganduje ti yayọ̀ pẹlu ọmọlẹyìn kristi orílẹ̀-èdè yi bi wọn ṣe sàjọyọ̀ ọdún Àjíǹde, ó pe wọn lati gbàdúrà fún iṣọkan, àlàáfíà, ìdúróṣinṣin ètò òṣèlú àti ọrọ̀ fún Nàìjíríà.
Alaga gbogbogbo náà pé…