Browsing Category
ÌRÒYÌN ÒSÈLÚ
This is a category for politics news
Aya Ààrẹ Gbè Ọgọ́rùn ún Mílíọ̀nù Kalẹ̀ Fún Àwọn Tó Lùgbàdí Ìjàmbá Ọkọ̀ Agbépo Dikko Tó Bú Gbàmù
Arábìnrin àkọ́kọ́ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Oluremi Tinubu ti gbé Ọgọ́rùn ún Mílíọ̀nù fún àwọn to lùgbàdí isẹ̀lẹ̀ Ìjàmbá ọkọ̀ agbépo Dikko tó bú gbàmù láti fi se ìrànlọ́wọ́ fún wọn.
Ó sọ pé, èyí ti òun se jẹ láti fi kún eléyìí ti…
Ìgbésẹ̀ Tó Tọ́ La Gbé Láti Fi Yọ Aṣòfin Ọbasá Nípò Olùdarí Ilé Aṣòfin Èkó Tẹnu Mọ́ Ọn
Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Èkó tẹnu mọ́ ọn pé, Ìgbésẹ̀ tó tọ́ ni àwọn fi yọ Olùdarí Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin tẹ́lẹ̀, Aṣòfin Mudashiru Ọbasá nípò.
Nínú àtẹ̀jáde wọn lẹ́yìn tí wọ́n fojú hàn ní ilé iṣẹ́ Ẹ̀ṣọ́ Àláàbò Ìjọba…
Alága Gbogbogbò Ẹgbẹ́ Òṣèlú APC Gba Ọmọ Ẹgbẹ́ Tuntun Ogójì Ẹgbẹ̀rún Wọlé Ní Ìpínlẹ̀ Katsina
Alága Gbogbogbò Ẹgbẹ́ Òsèlú APC, All Progressives Congress, Dokita Abdullahi Ganduje, ti gba ọmọ ẹgbẹ́ tuntun tó tó Ogójì Ẹgbẹ̀rún ti wọn sá kúrò látì ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹgbẹ́ òsèlú ní ìpínlẹ̀ Katsina wọlé sínú Ẹgbẹ́ Òsèlú APC.
Ganduje…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Katsina Jẹ́jẹ̀ẹ́ Láti Se Ètò Ìdìbò Ìjọba Ìbílẹ̀ Tí Kò Ní Ẹja-n-bákàn…
Gómìnà Ìpínlẹ Katsina, Dikko Umaru Radda ti ké sí ẹgbẹ́ òsèlú APC àti àwọn alẹ́nulọ́rọ̀ nínú ẹgbẹ́ náà láti pèpè àtìlẹyìn fún ẹgbẹ́ náà lójúnà àti jáwé olúborí nínú ètò ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ tí ó ń…
Kalu Kẹ́dùn Pẹ̀lú Àwọn Tí Ó Fi Ara Káásá Níbi Ìjàm̀bá Ọkọ̀ Epo Tí Ó Bú Gbàmù
Igbákejì Adarí Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Ọ̀gbẹ́ni Benjamin Okezie Kalu ti fi àìdùnnú ọkàn hàn lórí ìsẹ̀lẹ̀ láabi èyí tí ó wáyé látàrí bí ọkọ̀ epo se subú tí ó sì gbiná lẹ́ṣẹ̀-kẹṣẹ̀, èyí tí ó mú kí ọ̀pọ̀…
Ètò Ààbò Ni Ìpínlẹ̀ Oyo: Ilé Ìgbìmọ̀ aṣòfin Ìpínlẹ̀ Oyo Pọn dandan Nomba Ọkọ.
Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Ìpínlẹ̀ Oyo ti ṣe ofin wí pé ó Pon dandan fún gbogbo ọkọ́ láti ni nọmba ìdánimọ̀.
Wọn ní èyí yóò ṣe ìrànlọ́wọ́ fún ètò ààbò ni ìpínlẹ̀ náà.
Òfin yìí ni Ọ́nárébù R.A Mabaje láti ( Idọ), Ọ́nárébù Adebo Ogundoyin láti…
Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Èkó Pé Gómìnà Sanwo-Olu Láti Fọwọ́ Ọ̀kúnkúndùn Mú Ọ̀rọ̀ Àwọn Ajínri Àti…
Pẹ̀lú ìgbésẹ̀ láti fi dáàbò bo àwọn nǹkan ìní ìjọba àti ààbò àwọn ará ìlú lójú pópó, Ilé Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Èkó ti rọ Gómìnà Sanwo-Olu láti pàṣẹ fífi ọwọ́ ṣìnkún òfin mú àwọn olè akólè lójú pópó tí kò bá òfin mu.
Ilé Aṣòfin náà…
Olùdarí Ilé Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Èkó Ṣe Ìlérí Títẹ̀lé Ìlànà Ìṣàkóso Rere Àti Òdodo
Olùdarí Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Èkó, Aṣòfin Mojisola Meranda fi múlẹ̀ ní ọjọ́ Ẹtì, (Friday) tí í ṣe ọjọ́ àkọ́kọ́, tí yóò dárí Ìgbìmọ̀ Aṣòfin náà gẹ́gẹ́ bí Olùdarí Ilé náà lẹ́yìn tí wọ́n ti yọ, olùdarí àná, pé òun yóò ṣe ìjọba…
Aṣojú Sòfin Kẹ́dùn Ikú Ìyáàfin Oríyọmí Onanuga
Ilé ìgbìmọ̀ Aṣojú Sòfin ti kéde ikú Ìyáàfin Adewunmi Oriyomi Onanuga tó jẹ́ igbákejì Àgbà ilé ìgbìmọ̀ tó ń sójú fún Ikenne/Sagamu/Ariwa Remo Kòńsítúnsì Àpapọ̀ ìpínlẹ̀ Ògùn - Deputy Chief Whip of the House, representing the…
Gómìnà Gbósùbà Fún Sẹ́nétọ̀ Nwebonyi Látàrí Síṣe Ìrànlọ́wọ́ Fún Àwọn Ènìyàn…
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ebonyi, Ọ̀gbẹ́ni Francis Nwifuru ti sàpèjúwe Sẹ́nétọ̀ Onyekachi Nwebonyi gẹ́gẹ́ bi adarí rere tí ó nífẹ̀ẹ́ àwọn ènìyàn rẹ̀ atipe o jẹ ohun àmúyangàn fún ìpínlẹ̀ Ebonyi
Gómìnà sàpèjúwe ìgbésẹ̀…