Browsing Category
ÌRÒYÌN ÒSÈLÚ
This is a category for politics news
Adelabu Fi Èròǹgbà Rẹ̀ Hàn Fún Ipò Gómìnà Ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́
Igbakeji gomina ile ifowopamọsi apapọ ti Naijiria (CBN) tẹlẹri ati oludije fun ipo gomina nigba kan ri ninu ẹgbẹ oselu APC ni ipinlẹ Ọyọ lọdun 2019, Oloye Adebayo Adelabu ti sọ pe oun setan lati dije du ipo gomina ipinle naa, nigba keji,…
Omi yalé: FCTA rọ àwọn olùgbé láti gbọ́ ìkìlọ̀
Ilé-iṣẹ́ tó ń mójútó ètò olú-ìlú, (FCTA) ti rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí àwọn olùgbé láti gbọ́ ìkìlọ̀ tí ilé-iṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ tó ń rísí ọ̀rọ̀ pàjáwìrì , (FEMA) ńṣe fún wọn lásìkò, lẹ́yìn òjò tó rọ̀ lówùúrọ̀…
2023 Presidential election: Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkìtì Ṣèkéde Èròńgbà Láti Dije
Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkìtì ní Gúúsù iwọ̀ oòrùn orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Káyọ̀dé Fáyẹmí, ti kéde èròńgbà rẹ̀ láti díje du ipò ààrẹ lábẹ́ àsìá ẹgbẹ́ oṣelu All Progressives Congress, APC.
O soro yii ni…
Wọ́n sún ọjọ́ Ṣíṣàyẹ̀wò àwọn olùdíje fún ipò ààrẹ PDP,Gómìnà síwájú – NWC
Ìgbìmọ̀ àpapọ̀ ìṣiṣẹ́, (NWC) ẹgbẹ́ ti sún ọjọ́ ṣíṣàyẹ̀wò àwọn olùdíje fún ipò ààrẹ àti gómìnà láti ọjọ́ kẹta,oṣù karùn ún sí ọjọ́ kẹrin,oṣù karùn ún.
Bakannaa, igbimọ Alase apapọ ẹgbẹ People's Democratic…
Ọdún Ìtúnu Ààwẹ̀: Ọbasa ki àwọn mùsùlùmí kú oríire, ìrètí wà pé Nàíjíríà yóò dára…
Oludari Ile Igbimọ Aṣofin Ìpínlẹ̀ Eko, Aṣofin Mudashiru Ọbasa ti ki awọn musulumi kaakiri orile-ede Naijiria ku oriire ọdun Itunu Aawẹ tí wọn fi n parí Aawẹ Ramadan, ti o ṣe pataki ninu opo ẹsin Isilaamu.
Aṣofin Ọbasa tun kí àwọn…
Má baá iṣẹ́ rẹ̀ lọọ; Ààrẹ Buhari lósọ bẹ́ẹ̀ fún olùdíje ipò gómìná ti ìpínlẹ̀ ekiti:…
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti fi àsíá ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress (APC) fún ọ̀gbẹ́ni Abiodun Oyebanji tó jẹ́ olùdíje nínú ẹgbẹ́ náà nínú ìdìbò gómìnà ní ìpínlẹ̀ Èkìtì, tí yóò wáyé ní ọjọ́ kejìdínlógún oṣù kẹfà ọdún 2022.…
Gómìná Ìpínlẹ̀ Sokoto Ṣe Ìlérí Ìjọba Rere: Alhaji Aminu Tanbumwal
Olùdíje fún ipò ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjírìa nínu ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party (PDP), àti Gómìná ìpínlè Sokoto, Alhaji Aminu Tanbumwal sọ ní ọjọ́bọ̀ ní Abuja pe àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjírìa ti…
Ètò Ìdìbò Ọdún 2023 Yóò lọọ ní ìrọwọ́ rọsẹ̀: Ààrẹ Muhammadu Buhari
Ààrẹ Muhammadu Buhari gba àwọn tó ń gbèrò láti tako ìdìbò gbogbogbòò lọ́dún 2023 nímọ̀ràn pé kí wọ́n sọ ewé agbéjé mọ́wọ́, ó sì búra láti lo gbogbo ọ̀nà tó tọ́ láti dáàbò bo ìbò àwọn ọmọ Nàìjíríà. Èyí jẹ́ mímọ̀ nínú ìpàdé óúnjẹ…
Ọ̀gbẹ́ni Bola Tinubu, Fi Ìmoore Hàn Sí Àwọn Asòfin Ìpínlẹ̀ Èkó
Olùdíje Ààrẹ fún ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress (APC), Ọ̀gbẹ́ni Bola Tinubu, fi ìmoore hàn sí àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ìpínlẹ̀ Èkó fún ayẹyẹ tawaf àti ìpàdé àdúrà fún un ní Mekka, Saudi Arabia.…
Ìdìbò 2023: Mínísítà ìpínlẹ̀ fún ètò ẹ̀kọ́ ýòo díje ipò ààrẹ
Mínísítà fún ètò ẹ̀kọ́, Chukwuemeka Nwajiuba ti fìfẹ́ hàn sí gbígba fọ́ọ́mù ìdíje lábẹ́ àsìá ẹgbẹ́ All Progressives Congress Party,APC, fún ipò Ààre orílè-èdè Nàìjíríà.
Nigbati o ngba fọọmu naa ni Ọjọbọ,…