Browsing Category
ÌRÒYÌN ORÍLẸ̀-ÈDÈ NÀÍJIRÍÀ
This is a Nigeria news category
Àpérò VON Ọdún 2026 Fi Ìdarí Àkóso Ìjọba Àwaarawa Nàìjíríà Hàn Ní ECOWAS
Ile iṣẹ agbohun safefe Voice of Nigeria (VON), pẹ̀lú àjọṣepọ̀ pẹ̀lú Ilé Iṣẹ́ Àpapọ̀ fún Ìròyìn àti Ìlanilọ́yẹ̀ Orílẹ̀-èdè yii àti àwọn alenulọ́rọ̀ pàtàkì mìíràn, yóò pe àwọn olùṣètò òfin, àwọn aṣojú, àwọn onímọ̀ nípa ìròyìn, àti àwọn…
Ìpínlẹ̀ Kebbi Bẹrẹ Ìpínkiri Àwọn Ohun Èèlò Hájì
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Kebbi ti gbé ìpínkiri àwọn aṣọ, àpò àti hijabù sí àwọn amọ̀nà Hajj jákèjádò àwọn agbègbè ìjọba ìbílẹ̀ mọkanlelogun, gẹ́gẹ́ bí apá kan nínú ìmúrasílẹ̀ fún Haji ti ọdún 2026.
Ayẹyẹ náà wáyé ní Ilé Iṣẹ́ Kebbi State Pilgrims…
Ọjọ́ Ìlera Àgbáyé: Àjọ WHO Fẹ́ Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ Gbogbo Àgbáyé
Àjọ Ìlera Àgbáyé (WHO) ti rọ àwọn ènìyàn kárí ayé láti tún ìdúróṣinṣin wọn sí ìfọwọ́sowọ́pọ̀ ṣe àti láti ṣàtìlẹ́yìn fún ìmọ̀ sáyẹ́ǹsì gẹ́gẹ́ bí agbára ìdarí fún ìdarasi ìlera àgbáyé.
Àjọ náà ké sí àwọn ìjọba, àwọn ilé iṣẹ́ àti àwọn…
Ẹni Tó Ni Àmì Ẹyẹ Mo Yege Guinness World Records Parí Ìrìn Àjò Ìfaradà Rẹ̀ Ni Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà
Ẹni tó to ti gba ìwé àmì ẹ̀yẹ Guinness World Record, Kanyeyachukwu Tagbo-Okeke láti orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, fi ìfaradà àti ìpinnu hàn láti parí ìrìn àjò kẹ̀kẹ́ tó gùn tó ibusọ̀ to le ni ẹgbẹta Kilomita, 687KM láti Enugu sí Èkó ní Nàìjíríà,…
Ààrẹ Tinubu Kí Gbega Daniel Kú Oríire Ọjọ́ Ìbí Àádọ̀rin Ọdún
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu ti bu ọlá fún Sẹ́nétọ̀ Gbenga Daniel ní ọjọ́ ìbí ọdún àádọ́rin rẹ̀, ó sì ṣe àpèjúwe rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí onímọ̀ ẹ̀rọ olókìkí, oníṣòwò tó ṣe àṣeyọrí, olóṣèlú olókìkí, àti ọ̀rẹ́ korikosun àti ọ̀rẹ́ fún ìgbà pípẹ́.…
Aarẹ Bola Tinubu Yóó Se Ìfilọlẹ̀ Àwọn Àkànṣe Iṣẹ́ Amáyédẹrùn Pàtàkì Mẹ́fà Ni Ìlú Èkó
Aarẹ Bola Tinubu ti ṣetan lati ṣe ifilọlẹ awọn iṣẹ amayederun pataki mẹfa ti ìjọba Eko ṣe agbekalẹ rẹ bi o ti bẹrẹ abẹwo enu iṣẹ olọjọ meji si ipinlẹ naa.
Aarẹ ni ọjọ Ọjoru ati Ọjọbọ, Oṣu Kẹrin ọjọ kẹsan yoo ṣe ìfilọ́lẹ̀ akanṣe iṣẹ…
Adarí Nàìjíríà ṣèfilọ́lẹ̀ pápákọ̀ òfurufú Ogun, fìdí ìlọsíwájú orílẹ̀-èdè múlẹ̀
Ààrẹ Bola Tinubu ti ṣíṣọ lójú pápákọ̀ òfurufú káríayé ti nǹkan Ọ̀gbìn- Ẹrù ti Gateway àti àwọn iṣẹ́ àkànṣe amáyédẹrùn ní Ìpínlẹ̀ Ogun, tí ó sì ṣàlàyé wípé Nàìjíríà dúró ṣinṣin lóríi àti débi tó…
Ààrẹ Tinubu kò fọwọ́ yẹpẹrẹ mú àìláábò tí ń kojú Ẹkùn, Àgbáyé
Mínísítà Nàìjíríà fún ìbáraẹnisọ̀rọ̀ àti ìṣàlàyè, Mohammed Idris, sọ pé Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu ti túnbọ̀ tẹra mọ́ ìpè fún àtìlẹyìn ẹkùn àti àgbáyé láti kojú àìláábò ní Nàìjíríà àti láti dá…
Kò Lẹ́tọ̀ọ́ Láti Fi Ipò Aṣojú Orílẹ̀ Èdè Fún Àwọn Olóṣèlú – Ambassador Bolaji Akinremi
Akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ nípa ọ̀rọ̀ tó níí ṣe pẹ̀lú ilẹ̀ òkèèrè, Ambassador Bolaji Akinremi ti sọ di mímọ̀ pé kò lẹ́tọ̀ọ́ láti fún àwọn olóṣèlú ní ipò Aṣojú Orílẹ̀ èdè nítorí iṣẹ́ náà jẹ́ iṣẹ́ ìfẹ̀mí wéwu látàrí ìpèníjà tó rọ̀ mọ́ ọ.
Amb. Akinremi,…
Ààrẹ Tinubu buwọ́lu iye owó tó ju tíríọ́nù mẹ́ta lọ fún sísan gbèsè ẹ̀ka iná
Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu ti buwọ́lu iye owó tó ju tíríọ́nù mẹ́ta lọ gẹ́gẹ́ bí owó àsantán gbèsè ọlọ́jọ́ pípẹ́ , tó wànílẹ̀ fún ìṣàtúnṣe ní ẹ̀ka iná Nàìjíríà.
Alaye kan ti oludamọran pataki fun Aarẹ, Ọgbẹni Bayọ…