Take a fresh look at your lifestyle.
Browsing Category

ÌRÒYÌN ORÍLẸ̀-ÈDÈ NÀÍJIRÍÀ

This is a Nigeria news category

Ẹ Jẹ́ Aṣojú Rere – Makinde Gba Àwọn Ènìyàn Tó Fẹ́ Rin Ìrìn Àjò Hajj Odun 2024 Níyànjú

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti gba àwọn tó fẹ́ rin ìrìn àjò sí ilẹ̀ mímọ́ Saudi Arabia níyànjú láti jẹ́ aṣojú rere fún Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́. Makinde ló sọ èyí di mímọ̀ lásìkò ayẹyẹ ìdágbére fún àwọn ènìyàn Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti kò dín ní 1007…

Obìnrin Àkọ́kọ́ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ńfẹ́ Ìsọ̀kan Tó Pọ̀ Láàrín Orílẹ̀-èdè Adúláwọ̀

Obìnrin akọkọ Orílẹ̀-èdè Naijiria, Oluremi Tinubu ti sọ pé àwọn obìnrin jẹ́ òpó pàtàkì to gbé ilẹ̀ Áfíríkà ró, wọ́n sì tún jẹ́ ki àlàáfíà àti irẹpọ wà ni ilẹ̀ Adúláwọ̀. Ó sọ èyí nibi tó ti ń gbàlejò àjọ Organisation of African…

Ilé Aṣòfin Ipinlẹ Kogi Rọ Gómìnà Ododo Láti Túbọ̀ Múlele Lórí Ètò Ààbò Ní Àwọn Ilé Ẹ̀kọ́ Gíga Àgbà

Ilé aṣòfin ẹlẹ́ẹ̀kẹjọ ipinlẹ kogi ti rọ gomina Usman Ododo lati fi kun awọn eleto ààbò lati dẹkun ìwà ajinigbe ni ile ẹkọ gíga àgbà patapata ni ipinlẹ náà. Ọmọ ẹgbẹ igbimọ to soju ipin ẹka Adavi Kọ̀ǹsítúẹ́sì, Asema Haruna bú…

Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Àti Banki Àgbáyé Ṣèlérí Àtúnṣe Ilé Ẹ̀kọ́ Méjìdínlogota (58)

Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ pẹ̀lú àjọṣepọ̀ (Global Partnership for Education, GPE) ti Banki Àgbáyé ṣe àtìlẹ́yìn fún ti pèsè owó láti tún àwọn ilé ẹ̀kọ́ Ijoba Méjìdínlogota (58) ṣe. Ẹni tíì ṣe Kọmísánnà fun Ètò Ẹ̀kọ́, Sáyẹnsì ati Ìmọ Ẹ̀rọ ní…