
Browsing Category
ÌRÒYÌN ORÍLẸ̀-ÈDÈ NÀÍJIRÍÀ
This is a Nigeria news category
Abdulrahman Abdulrazak Ti Di Gómìná Ìpínlẹ̀ Kwara lẹ́ẹ̀kejì
Ajọ eleto Idibo INEC ti kede Olùdíje fún ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ All Progressive Congress, (APC), AbdulRahman AbdulRazak gẹgẹ bi oludije to jawe olubori ni ipinlẹ Kwara, ẹkun ariwa orilẹ-ede Naijiria
Alakoso Ibo ni Ipinlẹ naa àti Alakoso…
Dapo Abiodun ti wọlé lẹ́ẹ̀kejì Gẹ́gẹ́ Bíi Gómìná Ìpínlẹ̀ Ogun
Ajọ eleto Idibo ti kede Oludije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress (APC) ní Ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun gẹgẹ bi oludije to jawe olubori ninu ibo ọjọ satide
Alakoso Ibo ni Ipinlẹ naa, Ọjọgbọn Kayode Adebowale lo ṣe…
Adebayo Adelabu Ránṣẹ́ Ẹ kú Oríire Sí Gómìná Seyi Makinde
Olóyè Adebayo Adelabu ti ẹgbẹ òṣèlú Accord ti ranṣẹ ẹ kú oríire sí Gómìnà Seyi Makinde tí àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ dibo yan láti tù ọkọ ìṣèjọba lẹẹkan síi, tí o sì fi àsìkò náà rọ Gómìnà láti tẹ síwájú nínú iṣẹ réré fún wọn.
Olóyè…
Ọ̀rọ̀ Àkọ́sọ Seyì Makinde Gẹ́gẹ́ Bíi Gómìnà Fún Sáà Kejì Ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́
Lẹyin tí Àjọ Eleto Ìdìbò INEC ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ kéde Gómìnà Seyì Makide gẹgẹ bíi ẹni tí o jáwé olubori nínú ètò ìdìbò gómìnà to wáyé ní Àbámẹ́ta ọjọ Kejidinlogun oṣù yìí, Makinde fi ìdùnnú rẹ̀ hàn sí àṣeyọrí náà nígbà tí o n ba àwọn oníròyìn…
Sanwo-Olu Jáwé Olúborí Níbi Ìdìbò Gómìnà Ìpílẹ̀ Èkó
Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkó tí ó tún jẹ́ olùdíje sí ipò Gómìnà lábẹ́ ẹgbẹ́ òsèlú APC, Ọgbẹni Babajide Sanwo-Olu ti yege ní ìjọba ìbílẹ̀ méjìlélógún nínú ìjọba ìbílẹ̀ ogún tí ó wà ní ìpínlẹ̀ Èkó.
Àjọ INEC kéde èsì ìbò náà ní ọjọ́ Àìkú, ní gbọ̀ngàn…
Àbájáde Èsì Ìbò Gómìnà Ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́: Gómìnà Seyi Makinde Ti Ẹgbẹ́ Òṣèlú PDP Jáwé Olúborí Pẹ̀lú…
Èsì ìbò Gómìnà ní àwọn ìjọba Ìbílẹ̀ Mẹtalelọgbọn jakejado Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ fi hàn wí pé Gómìnà Seyi Makinde ti ẹgbẹ́ òṣèlú PDP lo jáwé olubori.
Gẹgẹ bíi Ọjọgbọn Bamire Adebayo tíì ṣe ọgá àgbà ilé ẹkọ gíga Fasiti OAU, tí o darí àkójọpọ̀…
Àkójọpọ̀ Èsì Ìdìbò Gómìnà Ti Bẹ̀rẹ̀ Ní Ìpínlẹ̀ Sokoto
Ìjọba ìbílẹ̀ méje ti bẹ̀rẹ̀ ìfiléde èsì ìdìbò wọn ní ìpínlẹ Sokoto
Lára àwọn ìjọba ìbílẹ̀ náà ni Binji, Wurno, Yabo, Isah, Gwadabawa, Tureta, ati Rabah.
Ètò àkójọpọ̀ èsì ìdìbò náà ń wáyé ní ọ́ọ́fìsì àjọ INEC ní ìlú Sokoto níbi tí àwọn…
Àkójọpọ̀ Èsì Ìdìbò Ń Lọ Lọ́wọ́ Ní Ìpínlẹ̀ Borno
Àkójọpọ̀ èsì ìdìbò fún ipò Gómìnà ti ń lọ lọ́wọ́ ní ìlú Maiduguri, olú ìlú Ìpínlẹ̀ Borno.
Ètò náà ń lọ lọ́wọ́ ní gbọ̀ngàn ilé ẹ̀kọ́ gíga sir Kashim ní ìlú Maiduguri. Níbi tí alákòsóo fún ìpínlẹ̀ náà Ọ̀jọ̀gbọ́n Jude Rabo ti ilé ìwé gíga…
Àkójọpọ̀ Èsì ìbò Gómìnà Gẹ́gẹ́ Bí Ò Ṣe Wáyé Ní Àwọn Ìjọba Ìbílẹ̀ Mẹ́tàlélọ́gbọ̀n Ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́
Akojọpọ èsì ìdìbò Gómìnà gẹgẹ bí o ṣe wáyé ni àwọn ìjọba Ìbílẹ̀ Metalelọgbọn (33) ni Ẹtì ọjọ Kejidinlogun oṣù yìí (18/03/2023) ní Ìpínlè Ọ̀yọ́ tí bẹrẹ, tí o sì n tẹ síwájú ni Gbongan Mutiu Agboke tó kalẹ sí Ọgbà Àjọ Eleto Ìdìbò INEC to wa…
Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Ẹlẹ́ẹ̀kẹẹ̀wá kò ní fi Ọwọ́ Yẹpẹrẹ Mú Ìpèsè Ohun Amáyédẹrùn- Lọla Ashiru
Sẹ́nétọ̀ Lọla Ashiru tí ó n sojú ibùdo ẹkun iwo òòrùn Ìpínlẹ̀ Kwara ní ilé ìgbìmọ̀ asòfin àpapọ̀ sàlàyé pé, ilé ìgbìmọ̀ asòfin àpapọ̀ ẹlẹ́ẹ̀kẹẹ̀wá tí yóò gbéra sọ láìpẹ́ yóò mú ìpèsè ohun amáyédẹrùn ní òkúkúdùn láti sọ ayé di gbẹdẹmukẹ fún…