Browsing Category
ÌRÒYÌN ORÍLẸ̀-ÈDÈ NÀÍJIRÍÀ
This is a Nigeria news category
Ilé Aṣòfin Èkó Rọ Gómìnà Èkó Láti Parí Àwọn Iṣẹ́ Akànṣe Tó Ń Lọ Lọ́wọ́
Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Èkó rọ Gómìnà Sanwo-Olu láti parí àwọn iṣẹ́ àkànṣe tó ń lọ lọ́wọ́, pàápàá iṣẹ́ àkànṣe ojú ọ̀nà márosẹ̀ Bọla Ahmed Tinubu lọ́nà Ìgbogbo Báyékù, tí wọ́n ti pa tì láti ọdún 2017.
Aṣòfin Aró Moshood tó ń…
Ìyàwó Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ṣe Ìdánilójú Iṣé Fún Àwọn Obìnrin.
Ìyàwó Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Oluremi Tinubu ti ṣe ìlérí ìdánilójú láti ran àwọn Obìnrin lọ́wọ́ ni Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Bákanáà ò sàlàyé wí pé Ààrẹ pàápàá kó gbẹyin láti ṣe Ìrànlọ́wọ́ àti àtìlẹ́yìn fún gbogbo àwọn Obìnrin nípa dídì ipo…
Ìgbógunti Dídá Abẹ Fún Ọmọbinrin, Ìdẹ́yẹsí Àti Àṣìlò Ọmọbinrin: Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Fi Ìgbìmọ̀…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti yan ìgbìmọ̀ ti yóò máa mójú tó ìgbógunti gbogbo ọ̀rọ̀ tó níí ṣe pẹ̀lú ìdẹ́yẹsí àti àṣìlò ọmọbinrin ni Ìpínlẹ̀ náà.
Ètò eléyìí to n ṣe àyajọ́ ọjọ́ ìdẹ́kun sí dídá abẹ́ fún ọmọbinrin lágbayé (International Day of…
Ààrẹ Tinubu Yìn Àjọ IFC Fún Owó Ìdókòwò Àádọ́ta Mílíọ̀nù Dọ́là
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu tí gbóríyìn fún àjọ tó ń rí sí ètò ìnáwó àgbáyé (IFC) fún owó ìdókòwò àádọ́ta mílíọ̀nù dọ́là ní àgbègbè Ọ̀fẹ́ ní Èkó.
Iyìn yìí wá latari ìgbàgbọ́ tí àjọ náà ní nínú ètò ọrọ àjé Nàìjíríà, Ààrẹ Tinubu nínú ọrọ…
Ilé Aṣòfin Èkó Pé Fún Mímú Ìdàgbàsókè Bá Ayẹyẹ Detty December
Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Èkó tí rọ Gómìnà Babajide Sanwo-Olu, àti àwọn ilé-iṣẹ́ ìjọba tọ́ rọ̀ kàn gbogbo láti mú Ìdàgbàsókè bá ayẹyẹ onífàájì ìparí ọdún, tí wọ́n pè ní' Detty December', kí ó lè di ayẹyẹ ìlú tí àwọn ará ìlú yóò gbárùkù tì.…
FUHSI VC Rọ́ Àwọn Ọmọ Ilé-ìwé Rẹ̀ Látí F’akọyọ Lórí Ètò Ẹ̀kọ́ Wọ́n Pẹ̀lú Ìwà Réré
Ìgbákejì Adarí (VC) tí Ilé-ìwé gíga 'Federal University of Health Sciences, Ila-Orangun (FUHSI)', Ìpínlẹ̀ Osun, Ọ̀jọ̀gbọ́n Akeem Lasisi tí rọ́ àwọn ọmọ ilé-ìwé rẹ̀ túntún látí kọ́ ẹ̀kọ́ àti ìhùwàsí tó dára.
Ọ̀jọ̀gbọ́n Lasisi sọ pé…
Ààrẹ Tinubu Kí Winifred Awosika Kú Ọjọ́ìbí
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu ti gbóríyìn fún Dókítà (Ìyáàfin) Winifred Awosika fún ìfara-ẹni-ṣápẹẹrẹ rẹ̀ sí ìdàgbàsókè ẹ̀kọ́ Nàìjíríà, ní àpèjúwe rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí oníṣòwò àti olùrànlọwọ.
Nínú ọrọ kán látí ọdọ Olùdámọ̀ràn pàtàkì Ààrẹ lórí…
Atiku Lọ Rí Obasanjọ Ní Abéòkúta Fún Ìpàdé Ìdakọ́nkọ́
Ìgbákejì ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà nígbà kan rí, Atiku Abubakar ti lọ rí ààrẹ tẹ́lẹ̀ rí, Olusegun Obasanjo ní ìlú Abeokuta, ìpínlẹ̀ ogun, gúsù ìwọ̀ oòrùn Nàìjíríà .
O dé sí ibugbe Obasanjo ní gbàgede Olusegun Obasanjo…
Orílẹ̀-èdè Israẹli Àti Nàìjíríà Yóò So Ètò Àjosepọ̀ Le Daindain Nípasẹ̀ Èròngbà Àjọ Alájọsepọ̀
Nàìjíríà àti Israẹli ti fi inú dídùn wọn hàn láti dá àjọ alájọsepọ̀ kan sílẹ̀ ti yóò mu ki ètò àjọsépò wọn tẹ̀ síwájú
Èyí ríbẹ̀ nígbàtí ilẹ̀ Isreali ti ṣetán láti ṣiṣẹ́ pọ̀ pẹ̀lú Nàìjíríà ni ti ẹka ètò ààbò, ọgbin, ìlera, ẹ̀kọ́…
Abúgbàmù Kankan kò wáyé ní ilé ìfọpo Warri – NNPCL
Ilé iṣẹ́ tí ń rísí ọ̀rọ̀ epo ilẹ̀ lórílẹ̀-èdè (NNPC), ti tako ìròyìn abúgbàmù ní ilé iṣé ìfọpo Warri (WRPC), tí wọ́n sí ṣàlàyé pé àwọn àtúnṣe ètò tó máa ń wáyé lóórè kóòrè nílé iṣẹ́ náà ló ń lọ…