Browsing Category
ÌRÒYÌN ORÍLẸ̀-ÈDÈ NÀÍJIRÍÀ
This is a Nigeria news category
Igbákejì Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàíjiríà bu ẹnu àtẹ́ lu pípa ọmọ ilé ìwé ní ìpínlẹ̀…
Igbákejì Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàíjiríà, Ọ̀jọ̀gbọ́n Yemi Osinbajo ti fèsì sí ikú ọmọ ilé ìwé Shehu Shagari College of Education, ìpínlẹ̀ Sokoto, ó se àpèjúwe ìṣẹ̀lẹ̀ náà gẹ́gẹ́ bi èyí tí kò bójúmu.
Deborah…
Ààrẹ Buhari kí Olórí orílẹ̀-èdè UAE Tuntun kú oríre
Ààre Muhammadu Buhari kí Ààrẹ titun ti United Arab Emirates, Sheikh Mohamed bin Zayed, tí ó jẹ Ààrẹ ìjọba nípasẹ̀ ìjọba àpapọ̀ ti ìjọba gẹ̀ẹ́sì láti dípò arákùnrin rẹ̀, Olóògbé Sheikh Khalifa Bin Zayed.
Ààrẹ…
Olórí Orílẹ̀-èdè Nàíjiríà bu ẹnu àtẹ́ lu pípa ọmọ ilé ìwé kan ní ìpínlẹ̀ sokoto…
Ààrẹ Muhammadu Buhari Bu ẹnu àtẹ́ lu iwa ibi tí àwọn jàndùkú ṣe ní ìpínlẹ̀ Sokoto, èyí tí ó yọrí sí ìwà ipá, bíba dúkìá jẹ́ àti pípa ọmọ ilé ẹ̀kọ́ Shehu Shagari College of Education, Sokoto,tí orúkọ rẹ̀ njé Deborah Samuel, lẹ́yìn…
Ọwọ́ Ajọ EFCC tẹ afurasí oníjibìtì ori ẹ̀rọ ayélujára mẹ́tàlélógún nílùú Ìbàdàn
Ajọ to n gbogun ti sise owo ilu kumo-kumo, (EFCC) ekun ti Ibadan ti mu awon afurasi onijibiti ori ẹrọ ayelujara metalelogun (23) ni ilu Ibadan ti i se olu ilu ipinle Oyo ni ekun gusu iwo oorun orile ede Naijiria.
Gege bi ọga…
Ẹ dìbò fún mi, gẹ́gẹ́ bí gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ láti mú àyípadà rere wá- Asofin Fọlarin
Asofin agba, Sentor Teslim Fọlarin naa ti fi erongba rẹ han lati dije du ipo gomina ninu eto idibo to n bọ.
Asofin Folarin, ẹni ti ogunlọgọ awọn ololufẹ rẹ ati ololufẹ ẹgbẹ́ oselu All Progressive Congress, APC tẹle lẹyin lait ṣ atiẹlyin…
Ẹ̀yin oníròyìn, ẹ jẹ́ kí ẹ̀mí yín wúlò ju isẹ́ ìròyìn lọ
Igbákejì Ọ̀gá àgbà Ilé ẹ̀kọ́ Fáfiitì Àjáyi Crowder, Ọ̀jọ̀gbọ́n Muyiwa Popoola ti gba àwọn oníròyìn níyànjú pé kò sí ìròyìn tó se iyebíye bí ẹ̀mí akọròyìn.
Ọ̀jọ̀gbọ́n Popoola ti o jẹ oludanilẹkọọ nibi eto ti…
Àwọn Olórí orílẹ̀-èdè Nàíjiríà Ṣọ̀fọ̀ Ikú Ààrẹ UAE, Late Sheikh Khalifa
Ààrẹ Muhammadu Buhari sọ pé ikú Ààrẹ orílẹ̀-èdè United Arab Emirates (UAE) Sheikh Khalifa Bin Zayed Al Nahyan ti jayé lólè ọ̀kan lára àwọn aṣáájú tó wúni lórí jù lọ lákòókò yìí.
Ilé-iṣẹ́ Ìjọba ti UAE ti kéde pé wọn yóò fi…
Mo ṣèlérí láti ran Orílẹ̀-èdè south sudan lọ́wọ́ – Aarẹ Muhammadu Buhari
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti ṣèlérí pé orílẹ̀-èdè Nàìjíríà yóò ran orílẹ̀-èdè South Sudan lọ́wọ́ láti gbógun ti ìwà ipá, àti dídá ìṣọ̀kan padà bọ́ sípò ní orílẹ̀-èdè náà.
Ààrẹ ṣe àdéhùn yìí ní ọjọ́ Jímọ̀ ní Ilé-ìgbìmọ̀…
À ń fé àtìlẹ́yìn ìlú òkèèrè nínú òṣèlú àwa obìnrin orílẹ̀-èdè Nàíjiríà…
Ìyáàfin Ààrẹ Nàíjiríà, Ìyáàfin Aisha Buhari, ti pe àwọn aṣojú orílẹ̀-èdè tí ó jẹ́ aṣojú ní orílẹ̀-èdè Nàíjiríà, láti ríi dájú pé àwọn obìrin ní ipa nínú òṣèlú.
Gẹ́gẹ́bí ọ̀rọ̀ ìyáàfin, èyí ti…
Ààrẹ Buhari bu ọwọ́ lu ìwé òfin mẹ́ta
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti buwọ́lu ìwé òfin, àwọn ìwé òfin mẹ́ta tí ó ní èrò láti dẹ́kun owó kíkójẹ lónà àìtọ́, àti dáá àwọn tí ó ń kówó fún aẁọn oníjàgìdíjàgan/Ìlànà ìnáwó ní Nàíjiríà.…