Take a fresh look at your lifestyle.
Browsing Category

ÌRÒYÌN ORÍLẸ̀-ÈDÈ NÀÍJIRÍÀ

This is a Nigeria news category

Ilé Aṣòfin Èkó Rọ Gómìnà Èkó Láti Parí Àwọn Iṣẹ́ Akànṣe Tó Ń Lọ Lọ́wọ́

Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Èkó rọ Gómìnà Sanwo-Olu láti parí àwọn iṣẹ́ àkànṣe tó ń lọ lọ́wọ́, pàápàá iṣẹ́ àkànṣe ojú ọ̀nà márosẹ̀ Bọla Ahmed Tinubu lọ́nà Ìgbogbo Báyékù, tí wọ́n ti pa tì láti ọdún 2017. Aṣòfin Aró Moshood tó ń…

Ìyàwó Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ṣe Ìdánilójú Iṣé Fún Àwọn Obìnrin.

Ìyàwó Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Oluremi Tinubu ti ṣe ìlérí ìdánilójú láti ran àwọn Obìnrin lọ́wọ́ ni Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Bákanáà ò sàlàyé wí pé Ààrẹ pàápàá kó gbẹyin láti ṣe Ìrànlọ́wọ́ àti àtìlẹ́yìn fún gbogbo àwọn Obìnrin nípa dídì ipo…

Ìgbógunti Dídá Abẹ Fún Ọmọbinrin, Ìdẹ́yẹsí Àti Àṣìlò Ọmọbinrin: Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Fi Ìgbìmọ̀…

Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti yan ìgbìmọ̀ ti yóò máa mójú tó ìgbógunti gbogbo ọ̀rọ̀ tó níí ṣe pẹ̀lú ìdẹ́yẹsí àti àṣìlò ọmọbinrin ni Ìpínlẹ̀ náà. Ètò eléyìí to n ṣe àyajọ́ ọjọ́ ìdẹ́kun sí dídá abẹ́ fún ọmọbinrin lágbayé (International Day of…

FUHSI VC Rọ́ Àwọn Ọmọ Ilé-ìwé Rẹ̀ Látí F’akọyọ Lórí Ètò Ẹ̀kọ́ Wọ́n Pẹ̀lú Ìwà Réré

‎ Ìgbákejì Adarí (VC) tí Ilé-ìwé gíga 'Federal University of Health Sciences, Ila-Orangun (FUHSI)', Ìpínlẹ̀ Osun, Ọ̀jọ̀gbọ́n Akeem Lasisi tí rọ́ àwọn ọmọ ilé-ìwé rẹ̀ túntún látí kọ́ ẹ̀kọ́ àti ìhùwàsí tó dára. ‎ ‎ Ọ̀jọ̀gbọ́n Lasisi sọ pé…

Orílẹ̀-èdè Israẹli Àti Nàìjíríà Yóò So Ètò Àjosepọ̀ Le Daindain Nípasẹ̀ Èròngbà Àjọ Alájọsepọ̀

Nàìjíríà àti Israẹli ti fi inú dídùn wọn hàn láti dá àjọ alájọsepọ̀ kan sílẹ̀ ti yóò mu ki ètò àjọsépò wọn tẹ̀ síwájú Èyí ríbẹ̀ nígbàtí ilẹ̀ Isreali ti ṣetán láti ṣiṣẹ́ pọ̀ pẹ̀lú Nàìjíríà ni ti ẹka ètò ààbò, ọgbin, ìlera, ẹ̀kọ́…
button