Browsing Category
ÌRÒYÌN ORÍLẸ̀-ÈDÈ NÀÍJIRÍÀ
This is a Nigeria news category
Àwọn ọmọ ológun Nàìjíríà mu àwọn oníjàgídíjàgan mẹ́rin balẹ nínú ìkọlù
Àwọn ọmọ ológun Nàìjíríà pa àwọn oníjàgídíjàgan mẹ́rin nínú isapamọ ati ikọlu ti o waye ni ipinlẹ Kaduna ati Katsina.
Alaye kan lati ọdọ Adari eto ibaraẹniṣepọ awọn ara ilu ti ologun, Ajagun Onyema Nwachukwu, sọ lasiko iṣẹ…
Ìpínlẹ̀ Ọyọ yóò yẹ́ ọba Olúbàdàn tó papòdà sí
Gómìnà Seyi Makinde, ti ìpínlẹ̀ Ọyọ ti sọ pé Ọba Aláyélúwà tí ó wàjà, Olúbàdàn ti ìlu Ìbàdàn, Ọba Mohood Lekan Balogun yóò gba ìyẹ́sí ìlú náà, nípa pé ìjọba yóò ri pé wọ́n ṣe ìsìnkú tó tọ́ fún un.…
Gómìna Oborevwori bẹnu àtẹ́ lu ìkọlù àwọn ológun, kẹ́dùn pẹ̀lú ẹbí àwọn olùfaragbà
Gómìna ìpínlẹ̀ Delta Gúsù Nàìjíríà, Ọ̀gbẹ́ni Sheriff Oborevwori ti bẹnu àtẹ́ lu, pípa àwọn òṣìṣẹ́ àti àwọn ọmọ ológun tó wà ní 63 Brigade, ní agbègbè Okuama, tó wà ní Agbègbè ìjọba ìbílẹ̀ Gúsù Ughelli ti…
Ààrẹ Tinubu yan Ja’afar Isa láti ṣadarí ìgbìmọ̀ Almajiri
Ààrẹ Bọla Tinubu ti buwọ́lu yíyan Ajagun fẹ̀yìntì Lawal Ja’afar Isa, ní Akọ̀wé Aláṣẹ fún ìgbìmọ̀ àwọn Àlìmájìrí lápapọ̀ àti fún ètò èkọ́ àwọn ọmọ tí wọn kò le tẹ̀síwájú lórí ẹ̀kọ́ wọn.
Ààrẹ tun buwọ́lu…
Àjọ Ẹ̀sọ́ Ẹnu Ibodè Se Àwárí Nǹkan Ogun Àti Àwọn Ẹrù Òfin Míràn Ní Ìpínlẹ̀ Ogun
Àjọ Ẹ̀ṣọ́ Ẹnu Ibodè, ẹka ti ìpínlẹ̀ Ogun ti se àwárí nǹkan ogun àti àwọn ẹrù òfin míràn èyí tí wọ́n kó wọlé lọ́nà àìtọ́ ní ẹnu ibodè ìpínlẹ̀ Ogun, Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà
Alákòóso àjọ náà ní ìpínlẹ̀…
Olúbàdàn Ti Ilẹ̀ Ibadan Wàjà, Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kwara, Àwọn Alẹ́nulọ́rọ̀ Sèdárò Lẹ́yìn…
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kwara, tí ó jẹ́ alága fún àwọn Gómìnà ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, AbdulRahaman AbdulRasaq ti darapọ̀ mọ́ àwọn ọ̀tọ̀ǹkùlú ènìyàn láti sèdárò lẹ́yìn olubadan kejìlélógójì, Ọba (Sen.) Lekan…
Àjọ Ọlọ́pàá Nílò Ọ̀pọ̀lọpọ̀ Owó Láti Tán Ìsòro Àìrajaja Ààbò- Ọba Alayé Pàrọwà
Ọba Alayé láti ìpínlẹ̀ Ọsun, Alayélúwà Ọba Oyelude Makama tí ó jẹ́ Olowu ti Kuta ni ó pè fún ìyàsọ́tọ̀ owó fún àjọ ọlọ́pàá, fún àseyọrí iṣẹ́
Ọba Makama pe ìpè náà ní ọjọ́ Ẹtì, níbi…
Aó Ṣe Ètò Ìsìnkú Alárinrin Fún Olúbàdàn Tó Di Olóògbé: Makinde
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti fi Olúbàdàn, Ọba Lekan Balogun, Allí Okunmade II tó di olóògbé wé ọmọluwabi ati ènìyàn jẹ́jẹ́ nígbà ayé rẹ̀, tó sì ṣèlérí pé ìjọba yóò ṣe ètò ìsìnkú rìnrìn fún un.
Gómìnà ló sọ ọ̀rọ̀ yi ni agbo ilé…
Adájọ́ Àgbà Tẹ́lẹ̀rí Dí Ẹni Ọdún Mọ́kànléláàdọ́ọ̀rún, Ààrẹ Tinubu Dáwọ̀ọ́ Ìdùnnú…
Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu dáwọ̀ọ́ ìdùnnú pẹ̀lú Adájọ́ Ilé Ẹjọ́ Gíga tẹ́lẹ̀rí, Emmanuel Obioma Ogwueghu nígbà tí ó di ẹni ọdún mọ́kànléláàdọ́ọ̀rún lónìí ọjọ́ kẹrìndínlógún osù kẹta ọdún 2024
Ààrẹ kí i…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Kwara Sanwó Ìtanràn Fún Àwọn Tí Ó Jọ̀wọ́ Ilẹ̀ Fún Ìdásílẹ̀ Ilé- Ìwé…
Alákòóso Ilé Iwé Gbogbonìṣe Ìpínlẹ̀ Kwara, èyí tí wọ́n dá sílẹ̀ ní ọdún 1973 ti sísọ lójú ọ̀rọ̀ pé, ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara ti sanwó ìtanràn fún àwọn ìdílé tí ó lé ní ọgọ́fà látàrí jíjọ̀wọ́ ilẹ́ fún…