Browsing Category
ÌRÒYÌN ORÍLẸ̀-ÈDÈ NÀÍJIRÍÀ
This is a Nigeria news category
Makinde Yan Alága Ìgbìmọ̀ Bọbajiroro Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Ati Awon Mẹ́jọ Míràn
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti yan Olóyè Adéwálé Àtàndá sínú ìgbìmọ̀ bọbajiroro (Advisory Council member) Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́.
Bákan náà ni Gómìnà tún yan ẹni to ti fi ìgbà kan rí jẹ́ Alága Ìjọba Ìbílẹ̀ Àríwá Ìlà Oòrùn Ìbàdàn àti ọmọ…
Ẹ Jẹ́ Aṣojú Rere – Makinde Gba Àwọn Ènìyàn Tó Fẹ́ Rin Ìrìn Àjò Hajj Odun 2024 Níyànjú
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti gba àwọn tó fẹ́ rin ìrìn àjò sí ilẹ̀ mímọ́ Saudi Arabia níyànjú láti jẹ́ aṣojú rere fún Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́.
Makinde ló sọ èyí di mímọ̀ lásìkò ayẹyẹ ìdágbére fún àwọn ènìyàn Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti kò dín ní 1007…
Àjọ FEC Buwọ́lù Ogún Tírílíọ̀nù Náírà Owó Ìfẹ̀yìntì Fún Àkànṣe Iṣẹ́ Ìdàgbàsókè
Àjọ Federal Executive Council(FEC) ti buwọ́lù Ogun Tírílíọ̀nù Náírà Owó Ìfẹ̀yìntì fún àkànṣe iṣẹ ìdàgbàsókè ni orílẹ̀-èdè yìí.
Mínísítà ètò isuna ati Mínísítà alakoso ọrọ ajé, Wale Edun ló sọ eyi leyin ìpàdé awọn àjọ FEC ti…
Obìnrin Àkọ́kọ́ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ńfẹ́ Ìsọ̀kan Tó Pọ̀ Láàrín Orílẹ̀-èdè Adúláwọ̀
Obìnrin akọkọ Orílẹ̀-èdè Naijiria, Oluremi Tinubu ti sọ pé àwọn obìnrin jẹ́ òpó pàtàkì to gbé ilẹ̀ Áfíríkà ró, wọ́n sì tún jẹ́ ki àlàáfíà àti irẹpọ wà ni ilẹ̀ Adúláwọ̀.
Ó sọ èyí nibi tó ti ń gbàlejò àjọ Organisation of African…
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kwara Yàn Tuntun, Se Àtúnyàn Àwọn Àgbà Àgbà Òṣìṣẹ́ Ilé Iṣẹ́ Ìjọba
Gómìnà ipinle Kwara,aarin gbùngbùn Ariwa orile-ede Naijiria AbdulRahman AbdulRazaq ti ṣe atuyan omobabinrin Bukola Babalola gẹgẹ bí igbakeji olori awọn oṣiṣẹ-Deputy Chief of Staff (DCOS).
Bi akọsilẹ lati ọdọ oga agba akowe…
Ilé Aṣòfin Ipinlẹ Kogi Rọ Gómìnà Ododo Láti Túbọ̀ Múlele Lórí Ètò Ààbò Ní Àwọn Ilé Ẹ̀kọ́ Gíga Àgbà
Ilé aṣòfin ẹlẹ́ẹ̀kẹjọ ipinlẹ kogi ti rọ gomina Usman Ododo lati fi kun awọn eleto ààbò lati dẹkun ìwà ajinigbe ni ile ẹkọ gíga àgbà patapata ni ipinlẹ náà.
Ọmọ ẹgbẹ igbimọ to soju ipin ẹka Adavi Kọ̀ǹsítúẹ́sì, Asema Haruna bú…
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kwara Dárúkọ Òṣìṣẹ́ Ìdàgbàsókè Ìjọba Ìbílẹ̀ Mẹ́rìndínlógún Tuntun
Gómìnà AbdulRahman AbdulRazaq ti ipinle Kwara, aarin gbùngbùn Naijiria ti buwọ́lù iyansipo awọn òṣiṣẹ Idagbasoke Ìjọba Ìbílè Mẹ́rìndínlógún
-16 local government area development officers (LGA-DOs).
Governor…
Àjọ USAID Fẹ́ Kọ́ Àwọn Àádọ̀rin Ọ̀dọ́bìnrin Ìpínlẹ̀ Bauchi Ní Ẹ̀kọ́ Nípa Ètò Ìmọ̀ Ìlera
Àjọ United States International Development Agency Health WorkForce Management (USAID-HWM) project sọ pe àwọn ṣetan lati kọ́ Àádọ̀rin Ọ̀dọ́bìnrin
ni ẹ̀kọ́ nipa ètò ìmọ Ìlera lati jẹ ki isẹ́ ètò ìlera ni ẹsẹ̀kùkú dán mọ́rán síi.…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Àti Banki Àgbáyé Ṣèlérí Àtúnṣe Ilé Ẹ̀kọ́ Méjìdínlogota (58)
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ pẹ̀lú àjọṣepọ̀ (Global Partnership for Education, GPE) ti Banki Àgbáyé ṣe àtìlẹ́yìn fún ti pèsè owó láti tún àwọn ilé ẹ̀kọ́ Ijoba Méjìdínlogota (58) ṣe.
Ẹni tíì ṣe Kọmísánnà fun Ètò Ẹ̀kọ́, Sáyẹnsì ati Ìmọ Ẹ̀rọ ní…
Aruna Quadri Tún Gbá Amí Ẹ̀yẹ ITTF Africa Cup
Gbájugbaja àgbábọ́ọ̀lù tẹ́nìsì orí tábìlì lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà Quadri Aruna tún gbá amí ẹ̀yẹ ìdíje ITTF Africa Cup 2024 lẹyìn tó ná Mohamed El-Beiali tí Egypt pẹlú amí ayo mẹ́rin sí odo (4-0) (11-5, 11-6, 12-10, 11-3) ní ìparí ìdíje náà,…