Take a fresh look at your lifestyle.

Ẹ Jẹ́ Aṣojú Rere – Makinde Gba Àwọn Ènìyàn Tó Fẹ́ Rin Ìrìn Àjò Hajj Odun 2024 Níyànjú

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti gba àwọn tó fẹ́ rin ìrìn àjò sí ilẹ̀ mímọ́ Saudi Arabia níyànjú láti jẹ́ aṣojú rere fún Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́. Makinde ló sọ èyí di mímọ̀ lásìkò ayẹyẹ ìdágbére fún àwọn ènìyàn Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti kò dín ní 1007…

Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Àti Banki Àgbáyé Ṣèlérí Àtúnṣe Ilé Ẹ̀kọ́ Méjìdínlogota (58)

Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ pẹ̀lú àjọṣepọ̀ (Global Partnership for Education, GPE) ti Banki Àgbáyé ṣe àtìlẹ́yìn fún ti pèsè owó láti tún àwọn ilé ẹ̀kọ́ Ijoba Méjìdínlogota (58) ṣe. Ẹni tíì ṣe Kọmísánnà fun Ètò Ẹ̀kọ́, Sáyẹnsì ati Ìmọ Ẹ̀rọ ní…

Ọwọ́ Sìnkú Àjò EFCC Tẹ Afurasí Onijibiti Orí Ẹ̀rọ Ayélujára Mẹrinlelogota (64) Ní Ìlú Ede

Pánpẹ́ Àjọ to n gbógun ti ṣíṣe owó ìlú kúmọ-kùmọ, EFCC ti mu àwọn afurasi onijibiti orí ẹrọ ayélujára tí kò dín ní Merinlelogota (64) ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun. Àwọn afurasi náà ni wọn kò sí i pánpẹ́ Àjọ EFCC, ẹkùn tí Ìbàdàn látàrí iṣẹ́ ìwádìí…

Gómìná Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Tẹ́lẹ̀ Rí, Dọ́kítà Omololu Olunloyo Ti Dágbére Fáyé 

Dọ́kítà Victor Omololu Olunloyo to jẹ Gómìná Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Tẹ́lẹ̀ Rí ni ọdún 1983 di Olóògbé. A bí Olóògbé ni ọjọ́ kẹrinla, oṣu kẹrin, ọdun 1935. Olóògbé Victor Olunloyo, jẹ gomina ni oṣu kẹwa, ọdun 1983 ni ipinlẹ ọyọ…

Gómìná Ìpínlẹ̀ Kogi Tẹ́lẹ̀ Rí Ti Di Ẹni Tí Ìjọbá Ń Wá Látàrí Ẹ̀sùn Kíkó Owó Ìlú…

Ìjọba Orílẹ̀-èdè Nàíjíríà ti fi Gómìná Ìpínlẹ̀ Kogi Tẹ́lẹ̀ Rí, Yahaya Bello si ori patako eni ti wọn n wa, wọn si ti fi to àwọn ologun Orílẹ̀-èdè Nàíjíríà àti awọn àjọ to n mójútó ìrìnà létí láti gbe ní…