Take a fresh look at your lifestyle.

Ọ̀nà Àbáyọ Si Ìdájọ Òdodo Àti Ìpẹ̀tù Sí Aáwọ̀: Aláàfin Ọ̀yọ́ Pé Fún Ìbáṣepọ̀ Láàrin Àṣà Yorùbá Àti…

Aláàfin ti Ìlú Ọ̀yọ́, Ọba Akeem Abímbólá Owoade I ti tẹnu mọ́ pé òun dúró digbí lórí èrò rere tí òun ni fún àwọn èniyàn Ìlú Ọ̀yọ́ àti ilẹ Yorùbá. Ọba Owoade , ẹni tó sọ di mímọ̀ pé ọ̀nà kan gbòógì láti mú àdínkù dé bá ìpèníjà to n kojú…

Aláàfin Ìlú Ọ̀yọ́ Ṣe Ìpàdé Pẹ̀lú Àwọn Oṣiṣẹ Ààfin, Pé Fún Ìsọ̀kan Láàrin Wọn

Aláàfin ìlú Ọ̀yọ́, Ọba Abímbólá Akeem Owoade I ti jẹ kó di mímọ̀ pé ìbáṣepọ̀ láàrin àwọn òṣìṣẹ́ kò ṣeé fi ọwọ́ rọ́ sẹ́yìn. Ọba Owoade tẹnu mọ́ pé ìbáṣepọ̀ tó dan mọ́ọ́rán ṣe pàtàkì fún isé àti iṣẹ́ ojoojúmọ́, tó sì tún jẹ́ ọ̀pákútẹ̀lẹ̀…

Aṣòfin Oluremi Tinubu Pé Fún Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ Olori Ìlú Láti Fòpin Sí Dídá Abẹ Fún Ọmọbìnrin (FGM)

Àyà Ààrẹ Orilẹ Èdè Nàìjíríà, Aṣòfin Oluremi Tinubu ti ké sí àwọn Olórí ìlú àti agbègbè láti sa ipá wọn lójúnà àti fi òpin sí dídá abẹ fún ọmọ obìnrin (FGM), kòkòrò HIV/AIDS àti àrùn jẹ̀dọ̀jẹ̀dọ̀. Oluremi Tinubu lo fi ọ̀rọ̀ lédè lásìkò tó…

Makinde Yan Alága Àti Ọmọ Ẹgbẹ́ Oṣiṣẹ Ìjọba Ìbílẹ̀, Ìgbìmọ̀ Irin Àjò Sí Ilé Mímọ́ Hajj.

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti bú ọwọ́ lu ìyànsípò alága àti àwọn ọmọ ẹgbẹ́ fún òṣìṣẹ́ ìjọba Ìbílẹ̀ àti àfikún ìgbìmọ̀ to n ri sì ìrìn àjò sí ilẹ̀ mímọ́, ẹka ti Musulumi. Ní ìbámu pẹ̀lú àtẹ̀jáde tí olórí àwọn òṣìṣẹ́ Gómìnà, Ṣẹgun…

Ayẹyẹ Ọdún Ajinde: Ẹ Gbé Ìgbé Ayé Tó Bu Ọlá Fún Ọmọnìyàn – Aláàfin Ọ̀yọ́

Aláàfin Ọ̀yọ́, Ọba Abímbólá Akeem Owoade I, ti gba ọmọ orilẹ èdè Nàìjíríà níyànjú láti pawọ́pọ̀ gbógun ti ìtàjẹ̀sílẹ̀ àti gbogbo ẹni yìówù tó sọ ará rẹ̀ di ọ̀tá ìlú tó n pa ènìyàn ni ìpakúpa. Ọba Owoade, ẹni tó korò ojú si ìwà ìpànìyàn…

Makinde Ke Sí Ọmọ Orílẹ̀ Èdè Nàìjíríà Láti Wá Dá Okòwò Sílẹ̀ Ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti ké sí ọmọ Orílẹ̀ Èdè Nàìjíríà láti wá da okòwò sílẹ̀ ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, nígbà tó fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé Ìpínlẹ̀ náà wà lójú iṣẹ́ lójúnà àti mú kí ọrọ̀ àjé gbèru síi nípasẹ̀ ètò ìgbáyé-gbádùn. Makinde ló…

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Tẹ́lẹ̀ rí, Ọmọlolu Olunlọyọ Jáde Láyé

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti fi ikú ẹni tó ti fi ìgbà kan rí jẹ́ Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Ọ̀mọ̀wé Victor Ọmọlolu Olunlọyọ wé àdánù nlá Makinde lo sọ ọ̀rọ̀ yìí nínù àtẹ̀jáde kan eléyìí to fi kẹ́dùn pẹ̀lú ìdílé Olunlọyọ, gbogbo ọmọ…
button