Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌDÁRAYÀ
This is a category for sport news
CAF Champions League: Power Dynamos Àti Rivers United Tá Ọmi
Ìgbésẹ̀ àkọ́kọ́ fún Rivers United láti ní àmì mẹ́ta lórí tábìlì nínú idije CAF Champions League láàrín ikọ náà ati power Dynamos, ni papa iṣere Levy Mwanawasa ní Ndola, Zambia lo wá sí òfo.
Rivers United ati Power Dynamos bẹrẹ pẹlu…
Manchester United fìdíẹ̀ múlẹ̀ pé Casemiro ti tẹ̀ síwájú gégẹ́ bíí òpin àdéhùn
Agbábọ́ọ́lù ipò ààrín fún Manchester United, Casemiro, yóò kúrò ní abala Premier League, tí sáà yí bá parí gẹ́gẹ́ bí òpin àdéhùn náà, ilé agbábọ́ọ́lù náà kéde.
Ọmọ ọdun mẹtale-lọgbọn naa le sun ọjọ naa…
’Rivers United’ Àti ‘Power Dynamos’ Tí Ṣetán Láti Kojú Ara Wọn Nínú Ìdíje…
Rivers United tí ṣetán fún ifẹsẹwọnsẹ pàtàkì tí ọjọ́ Àbámẹ́ta yìí, bí wọn yóò ṣé kojú ikọ̀ 'Power Dynamos FC' tí Zambia nínú ìdíje tí 'CAF Champions League'.
Ikọ̀ Rivers United tí gbéra lọ sí Ndola ni Zambia pẹ̀lú ìgboyà láti borí…
Osimhen, Lookman, Bassey Wà Lára Agbábọ́ọ̀lù Mọ́kànlá Ilẹ̀ Adúláwọ̀ Tó Dára Jùlọ Ti AFCON Ọdún 2025.
Àjọ Confederation of African Football (CAF), ti sísọ lójú eégún ní ojọ́ Ọjọ́rú agbábọ́ọ̀lù Mọ́kànlá Ilẹ̀ Adúláwọ̀ tó dára jùlọ ti AFCON Ọdún 2025 ti ikọ̀
Super Eagles orílẹ-èdè Nàìjíríà sì ní àwọn ògbóntàrigi akọni bíi
Victor…
Troost-Ekong Darapọ̀ Mọ́ Ẹgbẹ́ Qatar Al Ahli SC
Balógun Super Eagles ti Nàìjíríà tẹ́lẹ̀, William Troost-Ekong, tí buwọ́lù ìwé àdéhùn pẹ̀lú sí ẹgbẹ́ Qatar kán Al Ahli SC.
Troost-Ekong, ọmọ ọdún méjìlèlọ́gbọ̀n 32, agbábọ́ọ̀lù ẹyin kúrò nínú ẹgbẹ́ Saudi Al Kholood — níbi tó ti ń ṣé…
Wọn Yán Olumide Oyedeji Pẹ̀lú Ìbò Sí Ẹgbẹ́ Òlímpíkì Àgbáyé
Ọmọ Nàìjíríà, Olumide Oyedeji ní wọ́n tí yán gẹ́gẹ́ bí Akọ̀wé Gbogbogbò tí Ẹgbẹ́ Àwọn Òlímpíkì Agbaye.
Àtẹ̀jáde kán ní Ìpínlẹ̀ Èkó nípasẹ̀ Afolabi Oni, olùrànlọ́wọ́ ìròyìn rẹ̀, sọ pé Ó bóri Salvador Salguero ti El Salvador ati Liston…
Nàìjíríà Tí Wà Ní Ipò Kẹrìndínlọ́gbọ̀n Nínú Àkàbà ìdíje FIFA Tuntun
Ikọ̀ Agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà (Nigeria Super Eagles) ti wà ní ipò kẹrìndínlọ́gbọ̀n nínú àkàbà ìdíje FIFA tuntun, wọ́n sì ń gòkè sí ipò kẹta ní Áfíríkà.
Lágbàáyé, Spain ló dúró ní ipò àkọ́kọ́, lẹ́yìn náà ni Argentina àti Faransé, nígbà tí…
Ààrẹ Tinubu gbóríyìn fún ẹgbẹ́ Super Eagles fún àṣeyọrí ipò kẹta ní AFCON
Ààrẹ Bola Tinubu ti gbóríyìn fún ẹgbẹ́ agbábọ́ọ́lù Nàìjíríà, Super Eagles, bí wọn kò ṣe jé kí ìjákulẹ̀ ìpele kan kótó kan ti ìpari pẹ̀lú orílẹ̀-èdè tó gbàlejò ìfigagbága náà, Morocco dí wọn lọ́wọ́ láti…
Orílẹ-èdè Senegal Gbọ Ewúro Sí Ojú Orílẹ̀-èdè Morrocco Tí Wọ́n Sì Gbé Orókè.
Àwọn ẹgbẹ́ Agbábóòlù Orílẹ̀-èdè Senegal ni o gbà ife ẹyẹ ìgbà oróke níbí ìdíje bóòlù aláfesẹ̀gbà ti o wáyé láàrin àwọn orílẹ̀-èdè Áfíríkà lágbayé fún ìgbà Kejì.
Wọn gbà ife ìgbà oróke yìí leyin ìgbà ti wọn gbọ ewuro sí ojú àwọn ẹgbẹ́…