Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌDÁRAYÀ
This is a category for sport news
Ìdíje Ilẹ̀ Adúláwọ̀: Ikọ̀ Falconets Lù Ikọ̀ Senegal, Peregedé Fún Ipele Tó Kángun Sí Àsekágbá
Ikọ̀ agbabọọlu àwọn obìnrin Nàìjíríà ti ọjọ orí wọn ko kọjá ogun ọdun - Falconets ti lù ikọ̀ alatako won , Senegal bi ẹni lu aṣọ ofi ni ayo mẹrin sí ofo (4-0) ni papa isere Cape Coast. láti peregede sí ipele to kangun aí àsekagba.…
Orílẹ̀-èdè Angola Yóò Gbalejo Ìdíje Bọ́ọ̀lù Ajùsápẹ̀rẹ̀ FIBA Ọdún 2025
Angola ti gba anfààní láti gbalejo ìdíje
Bọọlu Ajusapere FIBA Ọdún 2025 tii se ọkàn lélọ́gbọ̀n irú rẹ̀ ti yóò wáyé ni oṣù kẹjọ ọdún ti n bọ̀. Orile-ede Morocco àti
Egypt ni wọn jọ du anfaani ìdíje bọọlu ajù sínú ajádìí apẹ̀rẹ̀…
Eré Ìdárayá Pais Ọdún 2024: Super Falcons Yóò Gbàlejò Banyana Ní Ọjọ́ Karùn-ún, Osù…
Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Super Falcons ti Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà yóò figa-gbága pẹ̀lú ojúgbà rẹ̀ Banyana Banyana ti Orílẹ̀-èdè South Africa nínú ìfẹsẹ̀ wọnsẹ̀ àkọ́kọ́ fún ìkójú òsùwọ̀n nínú bọ́ọ̀lù aláfẹsẹ̀gbá èyí…
Joshua Fi Ẹ̀yìn Ngannou Balẹ̀
Olùborí ẹsẹ kíkàn ìgbà méjì agbaye, Anthony Joshua ti fi ẹyin irawọ àkànṣe, Francis Ngannou balẹ̀ ni abala kejì ẹ̀sẹ́ kíkàn náà ni ọjọ́ Àbámẹ́ta.
Bí ojú Joshua se le koko to, o wá sí orí òkun ija pẹlu ìgboyà pé oun yóò bóri. Ki…
Ìdíje Ilẹ̀ Adúláwọ̀: Ikọ̀ Falconets Gbo Ewúro Sójú Ikọ̀ Morocco
Ikọ̀ Falconets orílè-èdè yìí daabobo àmì ẹyẹ goolu ti wọn gba látijọ́ nipa gbigbo ewuro soju ikọ̀ alatako won lati Morocco pẹlu ayo meji sí òdo (2-0) ni isori B ti wọn wa ni orile-ede Cape Coast ni alẹ́ ọjọ Ẹtì.
Ikọ̀ agbaboolu…
Cricket: Ikọ̀ Nàìjíríà Fi Ẹ̀yìn Ikọ̀ Namibia Gbolẹ̀
Ikọ̀ àwọn obìnrin ere Cricket Naijiria bẹrẹ daradara nibi ìdíje ere idaraya ile Adúláwọ̀ nibi ti wọn ti fi eyin ikọ̀ alatako wọn- Namibia gbolẹ̀ ti wọn sì yege ni ọjọ Ẹtì.
Ìdíje náà wáyé ni papa isere Achimota Secondary School…
Ikọ̀ Flying Eagles Nàìjíríà Subú Sọ́wọ́ Ikọ̀ Ti Uganda
Ni ìpele bọọlu alafesegba ti ìdíje ẹlẹẹkẹtala ile Adulawo to n lọ lọwọ ni orile-ede Ghana, iko Flying Eagles Nàìjíríà subu sowo iko Hippos ti ilẹ̀ Uganda pẹlu ayo meji sí ookan (2-1) ni papa isere Ifáfitì Accra, Ghana ni isori B…
Anthony Joshua Ti Gbáradì Láti Gbé Pẹ́rẹ́gi Ìjà Kaná Pẹ̀lú Francis Ngannou Ní Orílẹ̀-èdè…
Elẹ́sẹ̀ẹ́ kù bí òjò, Anthony Joshua ni ìrètí wà pé yóò figa-gbága pẹ̀lú ojúgbà rẹ̀ láti Orílẹ̀-èdè Cameroon, Francis Ngannou ní ọjọ́ Ẹtì, ní ìlú Riyadh, Orílẹ̀-èdè Saudi Arabia
Joshua àti Ngannou ni…
Bellingham Korò Ojú Sí Òté Ìdíje Méjì Tí Wọ́n Gbé Lée Lórí
Agbábọ́ọ̀lù àárín gbùngbùn ikọ̀ Real Madrid, Jude Bellingham ti koro ojú sí ote ìpàdánù ere ayo bọọlu meji ti wọn fi kan latari ìwà tó wú lori papa ti ko dara sí afunfere.
Àjọ Spanish Football Federation (RFEF) lo ni kí ọmọ…
Nadal Jáwọ́ Kúrò Nínú Ìdíje Indian Wells
Rafa Nadal ti jáwọ́ kuro ninu ìdíje Indian Wells ni ọjọ Ojoru ni ọjọ to ṣáájú ìdíje rẹ àkọ́kọ́, o so pe oun ko ṣetan lati kopa nibi to ga.
Ọmọ ọdún metadinlogoji náà ọmọ Spain
ti yóò feyinti leyin Sáà ọdún 2024
padà fún ìdíje…