Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌDÁRAYÀ
This is a category for sport news
Ikọ̀ Kano Pillar Lu Ikọ̀ Rangers Bí Ẹni Lu Aṣọ Òfì
Ikọ̀ Kano Pillars FC ti lu ikọ̀ tó wá déwọn lálejò pẹ̀lú ayò méjì sí oókan (2-) ni pápá ìseré Sani Abacha ni ìlú Kano nínú idije Nigeria Premier Football League (NPFL) ayo ọjọ ketadinlogbon.
Akọ́nmọ̀ọ́gbá ikọ̀ Super Eagles,…
Ikọ̀ Nàìjíríà Lulẹ̀ Nínú Ìdíje Tẹ́níìsì Ilẹ̀ Adúláwọ̀
Ikọ̀ Nàìjíríà subú jáde nínu Ìdíje Tẹ́níìsì àgbáyé - International Table Tennis Federation (ITTF) ti Ilẹ̀ Adúláwọ̀ ní ìlú Tunis, orílẹ̀-èdè Tunisia.
Ikọ̀ Canaan Queens ti Calabar tó ń sojú fún orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kọ́kọ́ fìdí…
Àjọ AIU Sọ Fún Ehoro Orí Ọ̀dàn Ọmọ Bíbí Kenya, Kipkorir Láti Lọ Rọ́kú Nílé Fún Ìgbà Kan
Ehoro orí ọ̀dàn ọmọbíbí ilẹ Kenya, Brimin Kipkorir ní wọ́n ti sọ fún kí ó lọ rọ́kú nílé fún Igba kan náà látàrí pè ō lulèẹ̀ ìdánwò mímu ògùn olóró tí wọ́n se fun. Àjọ Athletics Integrity Unit (AIU) ló sọ èyí.
Ọgbẹni Kipkorir…
Akọ́nimọ̀ọ́gbá Bú Lookman
Akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ Atalanta, Gian Piero Gasperini ti sọ pé ògbóntarigì agbábọ́ọ̀lù sáwọ̀n ọmọ Ilẹ Nàìjíríà ni, Ademola Lookman ni mùsè músè rẹ̀ kò dá músé músé níbi ki á gbá ayò golí wòó kí n gba síọ.
Ó sọ ayò nù tí o sì jẹ́…
Manchester United Pàdánù Ìfẹsẹ́wọ́sẹ̀ Wọ́n Pẹ̀lú Tottenham 1-0
James Maddison gbá ayo àkọkọ́ wọlé fún ìkọ Tottenham lẹ́yìn ifarapa rẹ̀ nínú ìdíje English Premier League bí wọ́n ṣé bóri ìkọ Manchester United pẹ̀lú ayo kán sí odò (1-0) ní ìlú London, England.
Èyí ní ìgbà àkọkọ́ tí Tottenham yóò…
Ikọ̀ Flying Eagles Nàìjíríà Yóò Koju Orílẹ̀-èdè Egypt, South Africa Àti Morocco
Olùgbadé ìdíje ni ìgbà méje, ikọ̀ Flying Eagles yóò koju ikọ̀ Egypt, South Africa àti Morocco ní ipele ibẹrẹ idije ọ̀jẹ̀ wẹ́wẹ́ ti ọjọ́ orí wọn kò kọjá ogún odún-U-20 Africa Cup of Nations (AFCON), ti yóò bẹ̀ryẹ ní ọjọ́…
Ìdíje NPFL: Ikọ̀ Akwa United Lu Ikọ̀ Enyimba FC Ní Uyo
Ikọ̀ Akwa United ba ẹtì àilèborí ni ìgbà mẹ́jọ ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ jẹ́ nípa gbígbo ewúro sójú ikọ̀ Enyimba FC pẹ̀lú ayò méjì si oókan (2-1) ni pápá isere Godswill Akpabio International ní ilu Uyo, ìpínlẹ̀ Akwa Ibom ní ọjọ́ Àìkú.
Jacob…
Áfíríkà Kí Ifè Ẹ̀yẹ Àgbáyé Káàbọ̀
Bó tí kú oṣù díẹ̀ tí ìdíje àgbáyé àwọn ẹgbẹ́ àgbábọ́ọ̀lù yóò fí wáyé ní orílẹ̀-ẹ̀dẹ̀ Amẹ́ríkà, Áfíríkà gbàlejò ifè túntún náà.
Ẹgbẹ́ agbabọọlu méjìlélọ́gbọ̀n 32 ní yóó kópa nínú ìdíje túntún náà níbí tí ẹgbẹ́ àgbábọ́ọ̀lù mẹ́rin yóò tí…
Ikọ̀ Agbábọ́ọ̀lù Kwara United Gbo Ewúro Sí Ojúgbà Rẹ̀ El-Kanemi Lójú Pẹ̀lú Àmì Ayò…
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Kwara United fi àgbà han ikọ̀ ti El-Kanemi nígbà tí ó jáwé olúborí pẹ̀lú àmì ayò méjì sí òdo, níbi ìfẹsẹ̀-wọnsẹ̀ tí ó wáyé ní pápá eré ìdárayá Rasidi Yẹkini, èyí tí ó wà ní ìlú…
A Ó Gba Ife Ẹ̀yẹ Wálé – NHF
Ààrẹ àjọ Nigeria Hockey Federation (NHF), Simon Nkom ti sọ pé ó dá òun lójú bí àdá pé ikọ̀ tó ń sojú wa ni ìdíje ọdún 2025 Africa Cup for Club Championship (ACCC) ni ilẹ̀ Ẹ́gípìtì, yóò ṣe àseyè tí alákàn ń sepo.
Ọgbẹni Nkom sọ…