
Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌDÁRAYÀ
This is a category for sport news
U-20 AFCON: Mínísítà fún ìdárayá gbóríyìn fún Nàìjíríà lẹ́yìn tí wọ́n gba…
Mínísítà fún ìdàgbàsókè ọ̀dọ́ àti ìdárayá, Sunday Dáre, ti gbóríyìn fún Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ́lù Flying Eagles, fún ipò kẹta tí wọ́n ṣe nínú ìdíje ife orílẹ̀-èdè Adúláwọ̀ (AFCON),U–20,ní Egypt.
Flying Eagles lu…
Senegal Gbá Ìfé U-20 AFCON Lọ́wọ́ Gambia Nínú Ìdíje TotalEnergies
Àwọn ọdọ Teranga Lions tí Senegal lú aladugbo rẹ̀ Gambia ní ọjọ́ Àbámẹ́ta látí gbà ìfé TotalEnergies U-20 Africa Cup of Nations.
Àmì ayò látí ẹ̀sẹ Sulaymane Faye àtí Mamadou Camara ní Olú-ìlú Egypt ní Cairo ló mú Senegal bórí…
Mínísítà Fún Eré Ìdárayá Rọ Ikọ̀ Flying Eagles Láti Ní Àfojúsùn Ife Ẹ̀yẹ Àgbáyé
Mínísítà fún ọ̀rọ̀ ọ̀dọ́ àti Eré Ìdárayá, Sunday Dáre, ti rọ ikọ̀ Flying Eagles láti dojú ìfojúsùn wọn kọ ife ẹ̀yẹ àgbáyé tó ń bọ̀ lọ́nà; Kí wọ́n gbàgbé ìjákulẹ̀ ayò kan sí òdo (1-0) tí ikọ̀ wọn pàdánù sí ọwọ́ ikọ̀ ti Gambia ní ìdíje Africa…
A Kò Sọ Ìrètí Nu!: Ẹlẹ́sèayò United
Ẹlẹ́sèayò Ẹgbẹ́ agbábọ̀ọ̀lù ikọ̀ Manchester United, Marcus Rashford ti fi lédè pe ikọ̀ òun kò sọ ìrètí nù nínú ìdíje àlùbami tí ìkọ̀ ti Liverpool lù wọ́n bí ejò àìjẹ ní ayò méje sí òdo. Ó wí pé, ikọ̀ òun kò gbọ́ ara wọn yé…
Mínísítà yóò gba àmìn ẹ̀yẹ ní Maldives
Wọn yóò dá Mínísítà Nàìjíríà fún eré ìdárayá àti ìdàgbàsókè ọ̀dọ́, Ọ̀gbẹ́ni Sunday Dáre lọ́lá pẹ̀lú ‘àmìn ẹ̀yẹ pàtàkì’ ní orílẹ̀-èdè Maldives.
Èyí jẹ́ fún ìmọ rírì ipa tÍ ó kó nínú…
U20 AFCON 2023: Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Gbà Flying Eagles Níyànjú Láti Gbé Ìfé Náà Wálé
Ààrẹ Muhammadu Buhari tí gbà àwọn àgbábọ́ọ̀lù Flying Eagles níyànjú láti gbà ìfé ìdíje CAF U-20 Africa Cup of Nations (AFCON) tó ń lọ lọ́wọ́ ní Egypt.
Flying Eagle yóò kojú Gambia lóni ní ìpele aṣekagba tí ìdíje náà pẹ̀lú bí wọ́n tí ṣé…
Ikọ̀ Agbábọ́ọ̀lù Arsenal Wà lókè Téńté Nígbà Tí Ó Lu Bournemouth Lálù-Bami
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Arsenal borí Bournemouth pẹ̀lú àmì ayò mẹ́ta sí méjì, èyí ló mú kí ó wà lókè té-ń-té pẹ̀lú àmì ayò márùn-ún nínú eré ìdárayá bọ́ọ̀lù aláfẹsẹ̀gbá tí ó ń lọ lọ́wọ́.
Àmì…
Mínísítà Fún Eré Ìdárayá Gbósùbà Rabandẹ̀ Fún Flying Eagles Látàrí Pé Wọ́n Gba Tíkẹ̀ẹ̀ti Àtikópa Ní…
Mínísítà Fún Eré Ìdárayá, Sunday Dáre ti gbósùbà ràbàndẹ̀ fún àwọn agbábọ́ọ̀lù Flying Eagles látàrí pé wọ́n gba Tíkẹ̀ẹ̀ti àtikópa ní Ìdíje Ife Àgbáyé ti yóò wáyé ni òpin ọdún yìí . O tún lù wọ́n lọ́gọ ẹnu pé wọ́n peregedé sí àbàlá…
Mínísítà Ìdárayá Kí Ààrẹ Túntún Tí Á Fibò Yàn Kú Oríìré
Mínísítà fún ìdàgbàsókè àwọn ọdọ àtí èrè ìdárayá, Sunday Dare tí kì Olúbóri nínú Ìdìbò Ààrẹ tí ọdún yìí, olùdíje fún ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress, APC, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu.
Ìkíni rẹ̀ tó wà nínú Gbólóhùn tí a samisi pé…
U-20 AFCON: CAF Kọ́ Ẹyìn Sí Pápá Ìṣéré Alexandria Fún Àwọn Ìfẹsẹwọnsẹ́ Tó Kù
Àjọ àgbábọ́ọ̀lù Ilẹ̀ Áfíríkà (Confederation of African Football CAF) tí gbé pápá ìṣéré Alexandria jù sílẹ̀ látí gbàlèjò àwọn ìdíje tí ń lọ́ lọ́wọ́ níbí ìdíje Adúláwọ̀ tí ọjọ́ orí wọ́n ó jù ogún ọdún lọ́, 2023 ní atẹle ẹdun ọkàn àwọn ẹgbẹ́…