Browsing Category
ÌRÒYÌN ILẸ̀ ÀFÍRÍKÀ
This is a category for Africa news
Àjọ UN Rán Ikọ̀ Adágun Dúró Lọ Sī Congo
Àjọ ikọ̀ alalaafia, United Nations peacekeeping mission ní Congo yoo ran ikọ̀ akọkọ rẹ láti mojuto idawọ́ ogun dúró láàrin ìjọba Congo àti ikọ̀ ọlọtẹ
AFC/M23 laipẹ ọjó die to n bọ̀. Minisiri ilé òkèèrè ti Quatar ló sọ èyí ní ọjó…
Ilé Ìfowopamọ́ Àgbáyé Gbé Ogún Mílíọ̀nù Dọ́là Kalẹ̀ Fún Àtunse Omí Yalé Ní Orílè-èdè Mozambique
Ilé Ifowopamọ Àgbáyé ti gbé Ogún Mílíọ̀nù Dọ́là Kalẹ láti ṣe iranlọwọ fún Orílè-èdè Mozambique Látàrí Omí yalé ti o n báwon Fira láti Ọdun to kọja
Nínú ọ̀rọ̀ tó Mínísítà fò jáde, O wí pè owó náà yóò jẹ ìrànlọ́wọ́ nla láti yanjú ijamba náà…
CAF Dá Olùkọ́ni Senegal Dúró Fún Rògbòdìyàn Ìdíje AFCON
CAF ti dá olùkọ́ni Senegal Pape Thiaw dúró fún ifẹsẹwọnsẹ márùn-ún, wọ́n sì tún bu owó ìtanràn ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rùn-ún dọ́là ($100,000) fún lórí ìwà tó kù díẹ̀ kaato tó wú lẹ́yìn tó sọ fún àwọn agbábọ́ọ̀lú rẹ̀ pé kí wọ́n kúrò lórí pápá…
Orílẹ̀-èdè Egypt Ti Fi Ẹsẹ̀ Ìbáṣepọ̀ Àwọn Ati Orílè-èdè US Músẹ̀ Ṣinṣin.
Mínísítà òkè òkun fún Orílè-èdè Egypt, Badr Abdel-Aty kí igbákejì Akọ̀wé Orílè-èdè US Christopher Landau káàbò sí Cairo fún ìtèsíwájú ìbásepọ̀ to san mórán láàrin Orílè-èdè méjèjì.
Àwọn méjèèjì sọ̀rọ̀ nípa àtúnṣe sí àwọn Orílẹ̀-èdè míràn…
Tunisia sọ àwọn gbajúgbajà akọ̀ròyìn méjì sẹ́wọ̀n ọdún mẹ́ta ààbọ̀
Ilé ejọ́ Tunisia dá ẹjọ́ tí ó sì sọ àwọn gbajúgbajà akọ̀ròyìn méjì sẹ́wọ̀n ọdún mẹ́ta ààbọ̀ lórí ẹ̀sùn yíyọ́ owó orí sílẹ̀, tí ìkan lára ẹbì sọ pé ìgbẹ̀san ìjábọ̀ tí wọn ń ṣe ni.
Awọn akọroyin naa, Bohran…
WHO Yàn Olùdarí Àgbègbè Túntún Tí Áfíríkà
Àjọ Àgbáyé fún Ìlera (World Health Organization WHO) tí kéde yíyan tí Ọ̀jọ̀gbọ́n Mohamed Janabi gẹ́gẹ́bí Olùdarí túntún fún Ẹkùn Áfíríkà tí WHO.
Yíyan náà ni a ṣé l'àkókò àpéjọ pàtàkì kán tí Ìgbimọ Àgbègbè WHO fún Áfíríkà, tó wáyé ní…
Ilé-ẹjọ́ orílẹ̀-èdè Adúláwọ̀ Àringbùngbùn fòhùntẹ̀ lu àtúnyàn Touaderá
Ilé-ẹjọ́ ofin orílẹ̀-èdè Adúláwọ̀ Àringbùngbùn, ni ọjọ́ Ajé ti fòhùntẹ̀ lu àseyege Ààrẹ Faustin-Archange Touadera, nínú ìdìbò Ààrẹ tó wáyé ní ọjọ́ kejìdín-lọ́gbọ̀n, léyìí tí ó jẹ́ kí ó máa lọ sí sáà…
Ikọ̀ Senegal Jáwé Olúborí Nípa Gbígbo Ewúro Soju Ikọ̀ Morrocco Ní Ìdíje Àsekágbá AFCON.
Ikọ̀ Teranga Lions of Senegal ní wọn gbade Olubori ajabori ti ilé Adúláwọ̀ fún ní igbà keji ninu ìtàn nipa gbígbo ewúro soju olugbalejo wọn, Morocco pèlú ayò kan dondo (1–0) lẹyìn afikun iseju ní pápá isere Stade Prince Moulay…
Nàìjíríà Fi Àjùlọ Han Egypt Nínú Ayọ̀ Golí Wòó Ki N Gba Síọ
Asọ́lé Stanley Nwabali di gbajumọ fún orílẹ̀-èdè Nàìjíríà bí Super Eagles se gba ami ẹyẹ "Bronze" níbi idije Africa Cup of Nations (AFCON), nínú ayò golí wòó ki n gba síọ - Pẹnáritì pèlú ayò merin sì meji (4-2) lẹyìn ìgbà ti idije…
Ìgbìmọ̀ Àjọ IMF Parí Àyẹ̀wò Owó Ẹlẹ́kẹ̀rin Orílẹ̀-èdè Ethiopia
Ìgbìmò àjọ IMF ti parí àyẹ̀wò ètò owó tó kẹ́yìn fún Orílẹ-èdè Ethiopia.
Ninu akọsilẹ, wọ́n sọ pé ètò náà
yóò fi àye silẹ láti sàn owó tó tó ọ̀kànlélọ́gọ̀ta-lé-nígba Dọ́là fún ìjọba Ethiopia.
Ìjọba ní Addis Ababa ti sọ tẹlẹ pe wọn…