Browsing Category
ÌRÒYÌN ILẸ̀ ÀFÍRÍKÀ
This is a category for Africa news
Àwọn Tó Ta Téru Nípàá Níbi Ìṣẹ̀lẹ̀ Ilé Dídàwó Lulẹ̀ Ní Orílẹ̀-èdè South Africa Jẹ́ Mẹ́tàlélọ́gbọ̀n
Àwọn to kú níbi iṣẹlẹ ile to dawọ lulẹ ni Orílẹ̀-èdè South Africa ti fò sí Mẹ́tàlélọ́gbọ̀n, mọ́kàndínlógún ènìyàn sì ti dì ẹni tí wọn ń wá.
Bí awọn adóòlà ẹ̀mi se n gbiyanju titi, kosi ẹni tuntun miran ti wọn ri, ènìyàn mẹ́fà…
Ológun Mẹ́ta Orílẹ̀-èdè Libya Kú Nínú Ikọlù
Ológun Mẹta Orílẹ̀-èdè Libya ti wọn fìkàlẹ̀ sí Tripoli ti ku nínú ìkọlù pẹlu àwọn agbógùn olóró ninu pápá to sunmọ orílẹ̀-èdè Algeria, bi ologun se sọ ni ọjọ Ìṣẹgun.
Ológun, 444 Brigade, sọ pé Ikọlu ati ija náà gbona janjan fun…
Ààrẹ Ramaphosa Bu Ẹnu Àtẹ́ Lu Àwọn Ènìyàn Tó Tako Àbá Ètò Ìlera
Ààrẹ ilẹ̀ South Africa, Cyril Ramaphosa ti fi ìdí èròngbà nipa ètò aba ìlera ti yóò fún mutumuwa ni ìlera pipe rẹ mule ki awọn eniyan lee gba wọlé.
Ètò aba ìlera apapọ ti o pé ni National Health Insurance (NHI) bill yóò fún…
Ilé-iṣẹ́ Ilẹ̀ Òkèèrè Tí America Nílùú Tanzania Tí Ilẹkùn Lórí Àìsí Íńtánẹ́ẹ̀tì
Ilé-iṣẹ́ ìjọba America ní Tanzania tí kéde titi ilẹ̀kùn fún ìgbà díẹ̀ fún ọjọ́ méjì nítorí àwọn ìṣòro nẹtiwọki tí ń lọ́ lọwọ́ ní orílẹ̀-èdè náà.
Nínú àlàyé òṣìṣẹ́ kàn, ilé-iṣẹ́ ilẹ̀ òkèèrè tí America tí kéde pé kìí yóò ṣiṣẹ́ ní ọjọ́…
Olórí Àwọn Alátakò Tí Chad Kọ́ Àbájáde Èsì Ìdìbò Ààrẹ Tó Wáyé
Olórí alátakò Chad sọ pé òún tí kó ẹsùn fún àwọn ìgbìmọ̀ t’olofin tí orílẹ̀-èdè náà látí kojú àwọn àbájáde tí Ìdìbò tó wáyé ní ọjọ́ kẹfà Oṣù Kàrún ọdún yìí.
Lórí ẹrọ́ ayélujára rẹ̀ ní ọjọ́ Àìkú, Succès Masra ṣàfihàn ẹda tí iwe-ẹri tó…
Àwọn Aláṣẹ Burundi Ń Bèèrè Fún Ìrànlọ́wọ́ Lórí Omí Yalé
Ìṣòro omí yalé tó ń dá wàhálà sílẹ̀ ní àgbègbè Ìlà-oòrùn Áfíríkà èyí tí Orílẹ̀-èdè Burundi ń bẹ́ nínú wọ́n, tí n pé fún ìrànlọ́wọ́ Àgbáyé látí kojú àwọn àbájáde tí Ojo nlá ń dá sílẹ̀.
Ní ìparí ọsẹ tó lọ́ ní ìjọ̀ba orílẹ̀-èdè Burundi…
Adarí Nàìjíríà ṣèlérí láti ṣàtìlẹyìn fún ààrẹ orílẹ̀-èdè Chad tí wọ́n dìbò…
Ààrẹ Nàìjíríà, Bọla Ahmed Tinubu ti fi dá ààrẹ orílẹ̀-èdè Chad tí wọ́n dìbò yàn, Mahamat Deby lójú pé Nàìjíríà yóò túnbọ̀ máa jọ ṣepọ̀ tímọ́tímọ́ pẹ̀lú orílẹ̀-èdè náà, tí ó sì ń kíi kú oríire…
Àwọn Aṣáájú Ní Nàìjíríà Yóò Kéde Àpéjọpọ̀ Ìgbóguntí Àwọn Apáníláyà Ní Abuja
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Bola Ahmed Tinubu yóò kéde ní Ọjọ́ Àjé, ọjọ́ kejílèlogún, Oṣù Kẹ́rìn, Ọdún 2024, tí yóò síi àpéjọ ìpàdé ìgbóguntí àwọn apáníláyà nílẹ̀ Áfíríkà ní Abuja, Olú-ìlú orílẹ̀-èdè náà.
Èyí ló dì mímọ̀ ní ọjọ́ Àìkú…
Àádọ́ta Àwọn Ènìyàn Kàn Pàdánù Ẹmí Wọ́n Nínú Ìjàmbá Ọkọ Ojú-omí Ni CAR
O fẹ́rẹ̀ jú àádọ́ta (50) ènìyàn tó lọ́ sìnkú ní abúlé kàn tí kú lẹyìn tí ọkọ Ojú-omí kékeré wọ́n dànù ní Olú-ìlú Central African Republic tí Bangui ní ọjọ́ Àbámẹ́ta, Òṣìṣẹ́ kàn sọ.
"Wọ́n tá wọ́n ní olobo lẹ́yin ogójì iṣẹju tí ìṣẹ̀lẹ̀…
Àwọn Àjà Fún Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn Tí Ojú-ọjọ́ Kenya Ṣé Ìwọ́de Ìkòrò Ojú Sí Àwọn Ilé-iṣẹ́ Èpò
Dọ̀sìnní àwọn ajà-fún-ẹ̀tọ́-ọmọnìyàn tí Ojú-ọjọ́ ṣé ìwọ́de ní òpópó-ònà tí Kisumu, Kenya látí fí ẹ̀honú hàn sí àwọn ilé-iṣẹ́ èpò rọbi ní àgbègbè wọ́n.
Ẹgbẹ́ náà n pé fún ifí òpin sí ìṣòro Ojú-ọjọ́ tó ń ṣẹlẹ̀ ní àgbáyé, àwọn amòye tí ṣé…