Browsing Category
ÌRÒYÌN ILẸ̀ ÀFÍRÍKÀ
This is a category for Africa news
Àwọn alájọṣepọ̀ ààrẹ Benin fi ẹ̀wọ̀n ogún ọdún gbára lórí ìgbèrò ìfipá gbàjọba
Àwọn arákùnrin méjì kan tí wọ́n súnmọ́ ààrẹ orílẹ̀ - èdè Benin, ti fi ẹ̀wọ̀n ogún ọdún gbára lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n mú wọn lọ́dún tó kọjá lórí ìgbèrò ìfipá gbàjọba lórílẹ̀ èdè náà.
Ile Ẹjọ ti n risi ẹṣẹ…
Àrùn Ebólà Bẹ́ Sílẹ̀ Ní Orílẹ̀-èdè Uganda
Orílẹ̀-èdè Uganda ti sọ àwídájú pé òtíttọ ni pé àrùn Ebólà ti sú yọ bi òsùmàrè ní olú ìlú orílẹ̀-èdè náà, Kampala pẹ̀lú ẹni àkọ́kọ́ tó lùgbàdí rẹ̀ bó se ń kú lọ ní ọjọ́ Ọjọ́rú, Mínísírì ètò ìlera sọ èyí ní ọjọ́ Ọjọ́bọ̀.
Ìgbà…
Orílẹ̀-èdè France Jọ̀wọ́ Ibùdó Ológun Ní Orílẹ̀-èdè Chad Sílẹ
Orílẹ̀-èdè France ti jọwọ Ibùdó Ológun rẹ̀ tó kẹ́yìn ní Orílẹ̀-èdè olómìnira Chad sílẹ̀, ibùdó Kossei ní N’Djamena. Oṣù méjì lẹ́yìn ti ilẹ̀ Chad sokùn àdéhùn ààbò le dain-dain pẹ̀lú ilẹ̀ Paris.
Bó tilẹ̀jẹ́pé ilẹ̀ Chad ló kéde òpin ìpínyà…
Ààrẹ Tinubu Pàdà Sí Abùjá Lẹ́yìn Ìpàdé Ní Tanzania
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu tí pàdà sí Olú-ìlú ní Abuja lẹ́yìn ìpàdé àwọn Olórí Orílẹ-èdè ní ilẹ̀ Áfíríkà ní Dar es Salaam, Tanzania.
Ní irọlẹ ọjọ́ Ìṣẹgun ní ọkọ òfurufú tí Ààrẹ balẹ̀ sí ilé-iṣẹ́ ọkọ Òfurufú tí Nnamdi Azikiwe ní Abuja ní…
Ààrẹ Tinubu Lọ Fún Ìpàdé Àpérò Ní Orílẹ̀-èdè Tanzania
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu ti balẹ̀ gùdẹ̀ sí Dares Salaam orílẹ̀-èdè Tanzania láti kópa níbi Ìpàdé apero ti wón pé ni "Mission 300 Africa Energy Summit" ti yóò bẹ̀rẹ̀ ní òní ọjọ́ kẹtàdínlọ́gbọ̀n.
Ààrẹ dé ni aago mẹ́jọ kọjá ogún…
Ikú Gómìnà Fa Awuye-wuye, Rúkè-rúdò Ní Orílẹ̀-èdè Congo
Àjọ Ọmọ Ogun ti Orílẹ̀-èdè DR Congo ti ń gbìyànjú láti dáàbò bo ará ìlú nígbà tí àwọn ọmọ ogun ọlọ̀tẹ̀ fìdí múlẹ̀ ní ìlú Goma, ní Ọjọ́ Ẹtì, èyí tí ó dá ìfòyà, wàhálà sílẹ̀ ní àgbègbè náà
…
Ẹgbẹ́ Òsèlú Democratic Alliance Gbé Pẹ́rẹ́gi Ìjà Kaná Pẹ̀lú Ìjọba Orílẹ̀-èdè South…
Ẹgbẹ́ òsèlú DA ti fi ojú ìjà hàn sí ìjọba tí ó wà lóde látàrí bí ìjọba se kùnà láti kó àkóyawọ́ èyí tí yóò fún gbogbo ẹgbẹ́ òsèlú láyè láti dásí ètò ìsèjọba, papàájùlọ nípa ètò ìlera àti…
Orìlẹ̀-èdè Senegal, Mauritania Bẹ̀rẹ̀ Ìpèsè Afẹ́fẹ́ Gáàsì
Orílẹ̀-èdè Senegal ati Mauritania ti ní àseyọrí aláìlẹ́gbẹ́ nígbà tí wọ́n darapọ̀ mọ́ awọn akẹgbẹ wọn ní àgbáyé gẹ́gẹ́ bi olùpèsè afẹ́fẹ́ Gáàsì èyí tí ó ń wáyé láàrin ẹnu ibodè Orílẹ̀-èdè méjéèjì náà…
Kémi Séba Kéde Èròńgbà Rẹ̀ Láti Díje Sí Ipò Ààrẹ Ní Ọdún 2026
Ajà-fẹ́tọ̀ọ́-ọmọnìyàn, Stellio Gilles Robert Capo-Chichi, ti gbogbo ayé mọ̀ sí Kémi Séba ti kéde èròńgbà rẹ̀ láti díje sí ipò ààrẹ ní Orílẹ̀-èdè Benin, èyí tí ìrètí wà pé yóò wáyé ní osù kẹrin ọdún 2026…
Àwọn Gómìnà Láti Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Péjú Síbi Ayẹyẹ Ìbúrasípò Ààrẹ Tí Wọ́n…
Gómìnà márùn-ún ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ láti Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ni ó ti gúnlẹ̀ sí ìlú Accra láti kópa níbi ayẹyẹ ìbúrasípò ààrẹ tí wọ́n dìbòyàn, John Dramani Mahama èyí tí yóò wáyé ní ọjọ́ ìṣẹ́gun ní gbọ̀ngàn…