Browsing Category
ÌRÒYÌN ILẸ̀ ÀFÍRÍKÀ
This is a category for Africa news
Orílẹ̀-èdè Kenya Yóò Dá Ìkólọ Ọlọ́pàá Sí Haiti Dúró Fún Ìgbà Díẹ̀
Ọgá agba oṣiṣẹ kan ninu Minisiri Kenya ti sọ pe, èròngbà kiko ọlọ́pàá lọ sí Haiti
yóò di sísorọ̀ latari ikede Olórí ìjọba Haiti, Ariel Henry to sọ pe oun ti ṣetan lati ju awa silẹ.
Ọgbẹni Sing’oei fikun pé Kenya yóò duro dè…
Rògbòdìyàn Sudan: Ológun Tún Olú Ìlú Ilé Ìròyìn Gbà
Ninu akosile kan, awọn ologun pe ni "aseyori nla".
Bí wọn tile ti gbàá lati oṣù kẹrin ọdún tó kọjá, awọn RSF kòleè gbohun safefe láti ibẹ, ile iṣẹ mohunmaworan kan tilẹ n fi ètò awọn ologun hàn lasan ni, eleyi n wáyé kaakiri…
Ààrẹ Angola Yóò Sàbẹ̀wò Sí Orílẹ̀-èdè China Láti Ọjọ́ Kẹrìnlá Sí Ọjọ́ Kẹtàdínlógún
Ààrẹ Angola yóò ṣe abewo sí Orílẹ̀-èdè China ni ọjo Kẹrìnlá sí ọjọ Kẹtàdínlógún, Mínísítà ọrọ nipa ìlú òkèèrè lọ sọ eyi ni ọjọ Ìṣẹ́gun .
Minisiri nibi ìròyìn igbagbogbo sọ pé Ààrẹ China - Xi yóò ni ìfọ̀rọ̀ jomitoro ọrọ pẹlu…
Ará Sá Ní Mozambique, Ó Sekúpa Ènìyàn Mẹ́rin
Ènìyàn mẹ́rin pàdánù ẹ̀mí tí àwọn mẹ́ta míràn farapa yánna-yànna níbi ìsẹ̀lẹ̀ àrá tí ó wáyé ní ìlú Mogincual, Orílẹ̀-èdè Mozambique
Àfojúsùn ti wáyé tẹ́lẹ̀rí nípa ìsẹ̀lẹ̀ àrá ní ọjọ́ iwájú…
Ọjà Gbówó Lórí Ní Orílẹ̀-èdè Niger Gẹ́gẹ́ Bí Ààwẹ̀ Ramadan Se Bẹ̀rẹ̀
Gẹ́gẹ́ bí osù ààwẹ̀ Ramadan se bẹ̀rẹ̀ fún àwọn mùsùlùmí Orílẹ̀-èdè Niger, níse ní gbogbo ọjà gbówó lórí, tí ó sì sòro fún ará ìlú láti rà wọ́n
Ètò ìdìtẹ̀gbàjọba ni ó ti kóbá ọrọ̀ ajé…
Orílẹ̀-èdè Ethiopia Àti TPLF Ti Sọ̀rọ̀ Ní Ìtùbí-ìnùbí Kí Àlàáfíà L e è Jọba…
Orílẹ̀-èdè Ethiopia àti àwọn asojú Tigray ti sọ̀rọ̀ ní ìtùbí-ìnùbí láti wá ojútùú sí wàhálà tí ó ń wáyé àti ìmúlò àdéhùn àlàáfíà tí ó wáyé ní osù kọkànlá ọdún 2022
Ìfọwọ́sí…
Ìbò Senegal: Gambari yóò darí àwọn awòye ECOWAS
Ọ̀jọ̀gbọ́n Ibrahim Gambari ni yóò darí àwọn ikọ̀ awòye ECOWAS fún ìbò ààrẹ Senegal, tí yóò wáyé ní ọjọ́ kẹrìnlé-lógún, oṣù kẹta, ọdún yìí.
Kọmiṣọna ECOWAS fun ọrọ oṣelu, Alaafia, ati Aabo, Aṣoju Abdel-Fatau Musah,…
Ààrẹ Senegal Kéde Ọjọ́ Ìdìbò Oṣù Kẹ́ta
Ìjọba orílẹ̀-èdè Senegal ti kéde pé idibo sí ipò ààrẹ yóò wáyé ni ọjọ kẹrìnlélógún oṣù keta.
Ikede yi ri bẹẹ latari awuyewuye isunsiwaju ti ààrẹ Macky Sall ti kọkọ se losu to koja, to fa iwode to tan kaaakiri bí ina igba ẹ̀rùn…
Àwọn Méjì Pàdánù Ẹmí Wọ́n Nínú Ìjàmbá Ọkọ̀ Òfurufú Ní Kenya
Ènìyàn méjì ní ìròyìn ṣàfihàn pé ó kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ Òfurufú kàn, láàrín ọkọ̀ òfurufú akẹ́kọ̀ọ́ kàn àtí ọkọ̀ òfurufú akérò kàn ní Olú-ìlú Kenya ní Nairobi, àwọn ọlọ́pàá àgbègbè náà sọ ní ọjọ́ Ìṣẹ́gun.
Ìṣẹlẹ̀ náà wáyé ní aago mẹ́wàá…
Somalia Dí Ọmọ Ẹgbẹ́ Ìlà-òòrùn Áfríkà Ní Kíkún
Somalia tí dí ọmọ ẹgbẹ́ Àwùjọ Ìlà-òòrùn Áfíríkà (EAC) ní kíkún.
Níbí ayẹyẹ kúkúrú kàn ní ilè-ìgbìmọ̀ EAC ní Arusha, Tanzania, Mínísítà fún Ìṣòwò tí Somalia, Jibril Abdirashid Haji, bí akọ̀wé Gbogbogbò tí ẹgbẹ́ ṣé àfihàn ìwé ìgbà wọlé…