Take a fresh look at your lifestyle.

Mínísítà rọ àwọn akọ̀ròyìn lórí ìròyìn déédé àti ọ̀rọ̀ ọlọgbọ́n

Ilé iṣẹ́ Nàìjíríà tí ń mójútó ètò ìbáraẹnisọ̀rọ̀ ti ṣe ìfilọ́lẹ̀ ìpele kejì ìbáraenisọ̀rọ̀ ilé iṣé náà fún ọdún 2025, tí ó sì rọ àwọn akọ̀ròyìn láti fi ìròyìn déédé, ìwọ̀ntún wọ̀nsì, àti ìsòdodo…

VON, NADDC yóò fọwọ́sowọ́pọ̀ láti ṣàgbélárugẹ abala ọkọ̀ Ayọ́kẹ́lẹ́

Ilé Akéde Nàìjíríà (VON) àti ilé iṣẹ́ tí ń rí sí Ìyàwòrán àti Ìdàgbàsókè ọkọ̀ Ayọ́kẹ́lẹ́ lórílẹ̀-èdè (NADDC), ń fọwọ́sowọ́pọ̀ láti ṣe àgbélárugẹ ìdàgbàsókè abala ọkọ́ Ayọ́kẹ́lẹ́ Nàìjíríà. Lasiko…

Arábìnrin Àkọ́kọ́ Nàìjíríà yóò ró àwọn obìnrin tó lé ní ẹgbẹ̀rún méjìdín-lógún…

Lórí ṣíṣa ipá rẹ̀ láti ró àwọn obìnrin lágbára fún ọrọ́ ajé àti ìdàgbàsókè àtile dá dúró, pàápàá jul̀ọ ní àwọn ìgbèríko, Arábìnrin Àkọ́kọ́ Nàìjíríà, Oluremi Tinubu, ti ṣe ìfilọ́lẹ̀ ètò…

Àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ Naijiria bèèrè fún Ìṣojú nínú ìgbìmọ̀ NELFUND

Ẹgbẹ́ àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ Naijiria lapapọ, NANS, ti bèèrè fún Ìṣojú nínú apejọ ìgbìmọ̀ tí ń rí sí Owó yíyá fún Ẹ̀kọ́ ní Nàìjíríà, NELFUND, pé bí àwọn ṣe jẹ́ olùjàǹfààní àkọ́kọ́ fún owó yíyá náà, wọ́n…

Mínísítà kí Ìyáàfin Tinubu kú oríire fún yíyàn án ní ọmọ ẹgbẹ́ ìgbìmọ̀ Alákòóso…

Mínísítà fún Ọ̀rọ̀ àwọn Obìnrin, Imaan Sulaiman-Ibrahim, ti kí Arábìnrin kìíní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Sẹnetọ Oluremi Tinubu, lóríi bí wọ́n ṣe yàn án  ní ọmọ ẹgbẹ́ ìgbìmọ̀ Alákòóso àwọn Arábìnrin Àkọ́kọ́…

Arábìnrin Kìínní Nàìjíríà di ọ̀kan lára ọmọ ẹgbẹ́ ìgbìmọ̀ alákòóso OAFLAD

Wọ́n ti yan Arábìnrin Kìínní Nàìjíríà, Oluremi Tinubu gẹ́gẹ́ bí ọmọ ẹgbẹ́ igbìmọ̀ Alákòóso fún Àjọ àwọn Arábìnrin kìíni fún Ìdàgbàsókè (OAFLAD), ipele Ìṣàkóso tó ga jùlọ nínú ẹgbẹ́ náà. Eleyi waye…
button