Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌLERA
This is a category for health news
WHO Yàn Olùdarí Àgbègbè Túntún Tí Áfíríkà
Àjọ Àgbáyé fún Ìlera (World Health Organization WHO) tí kéde yíyan tí Ọ̀jọ̀gbọ́n Mohamed Janabi gẹ́gẹ́bí Olùdarí túntún fún Ẹkùn Áfíríkà tí WHO.
Yíyan náà ni a ṣé l'àkókò àpéjọ pàtàkì kán tí Ìgbimọ Àgbègbè WHO fún Áfíríkà, tó wáyé ní…
Orílẹ-èdè Nàìjíríà Ṣe Ìfilọ́lẹ̀ Àwọn Ìgbìmọ̀ Nípa Ẹ̀tò Ìlera.
Ìjoba Orílẹ-èdè Nàìjíríà ti yan àwọn mẹ́rìnlelógún láti wakọ agbára fún ètò ìlera, ìgbìmọ̀ èyí to da lórí bi iná mọ̀nàmọ́ná yóò ṣẹ wa ni àwọn ilẹ iwosan ìjoba kakakiri.
Ìgbìmọ̀ yìí yóò rì dani wí pè ki o to di ọdún 2027 àwọn ilẹ iwosan ti…
Àwọn Dókítà bèèrè fún ìgbàpadà àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn tí wọ́n dá dúró lẹ́nu iṣẹ́
Ikọ̀ Àringbùngbùn –Àrewa ti Ẹgbẹ́ àwọn Àgbàa Dókítà (ARD), ti panupọ̀ béèrè fún gbígbà padà àwọn ẹlegbẹ́ wọn tí wọ́n dá dúró lẹ́nu iṣẹ́ ní Ilé Ìwòsàn Olùkọ́ni tìjọba àpapọ̀ (FTH), ti Lokoja, ní ìpínlẹ̀ Kogi,…
Ẹgbẹ́ ran àwọn tó ye ààrun jẹjerẹ ọyàn bọ́ lọ́wọ́ ni Anambra
Ẹgbẹ́ àwọn obìnrin ìpínlẹ̀ Anambra, ní Amẹ́ríkà Inc. àti Ẹgbẹ́ obìnrin ìpìnlẹ̀ Anambra ti Amẹ́ríkà tí ń rí sí Àjọṣepọ̀ lórí ààrùn jẹjẹrẹ ní Nàìjíríà, ti ṣàkójọ owó tó tó mílíọ́nù náìrà mẹ́ta láti ran…
Ìpínlè Anambra: Ṣẹ́nítọ̀ Bí Ẹnu Àtẹ Lu Bí Wọn Ṣe Ti Ọjà Onitsha Pa Fún Ìgbà Pípẹ́.
Dọ́kítà Tony Nwoye to jẹ Ṣẹ́nítọ̀ to n sojú ìpínlẹ̀ Anambra ti bu ẹnu àtẹ lù bí wọn ṣe tí ọjà Ogbo Ogwu ti wa ni onitsha pa fún ìgbà pípẹ́ báyìí
Ó ni àwọn ilé ìtajà to to egbegberun márùn-un ni àjọ tó n mójú tó ọrọ oúnjẹ àti ògùn NAFDAC…
Ipinlẹ Anambra Gbé Ìgbésẹ Akínkanjú Nípa Títún Àyíká Àti Bèbè Omi Ṣe.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Anambra pẹ̀lú àjọsọpọ̀ - "Initiative for Agulu Development" ní ọnà láti ṣe ìmọ́tótó sì àwọn agbègbè ti omi wà àti àwọn àyíká rẹ àti ni ọ̀nà láti jẹ́ kí ẹ̀gbin omi dínkù, wọn ti ṣètò ìmọ́tótó ní gbogbo bèbè omi àti ètò…
WHO Yàn Olùdarí Àgbègbè Túntún Tí Áfíríkà
Àjọ Àgbáyé fún Ìlera (World Health Organization WHO) tí kéde yíyan tí Ọ̀jọ̀gbọ́n Mohamed Janabi gẹ́gẹ́bí Olùdarí túntún fún Ẹkùn Áfíríkà tí WHO.
Yíyan náà ni a ṣé l'àkókò àpéjọ pàtàkì kán tí Ìgbimọ Àgbègbè WHO fún Áfíríkà, tó wáyé ní…
FRSC J’àbọ̀ Adínkù Ìjàmbá Ọkọ Ṣùgbọ́n Ìjàmbá Olóró Ń Pọ Sí
Àwọn Ẹ̀ṣọ Ojú Pópó Tí Ìjọba Àpapọ̀ (Federal Road Safety Corps FRSC) tí j'àbọ̀ ìròyìn adínkù ìdá mẹ́wàá 10% lápapọ̀ àwọn ìjàmbá òpópó-ọ̀nà láàrin ọdún 2023 àti 2024, sùgbọ́n ìdá méje 7% ní àwọn tó f'ara gbá ìjàmbá náà tó kú.
Corps…
NGO ní òun ti ní ipa lórí àwọn ènìyàn méjìlé-lọ́gbọ̀n Mílíọ́nù ní abala ìtọ́jú…
Ilé iṣẹ́ tí kìí ṣe tìjọba kan, Nigeria Solidarity Support Fund, NSSF, ti sọ pé òun ti ní ipa lórí àwọn ènìyàn méjìlé-lọ́gbọ̀n Mílíọ́nù ní ọdún mẹ́rin tí òun ti ń ṣiṣẹ́ ní abala ìtọ́jú ìlera lórílẹ̀-èdè.…