
Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌLERA
This is a category for health news
Ọ̀pọ̀ Ènìyàn Pàdánù Ẹ̀mí Látàrí Àìsàn Lassa Tí Ó Súyọ
Kò dí ní ènìyàn márùndíláàdọ́run tí wọ́n pàdánù ẹ̀mí láàrin ọ̀sẹ̀ mẹ́fà nínú ọdún 2023. Ìsẹ̀lẹ̀ náà wáyé ní ìpínlẹ̀ ogún léyìí tí ó sì kárí ìjọba ìbílẹ̀ mọ́kàndílọ́gọ́rin ní àwọn ìpínlẹ̀ náà…
Kọmíṣọ́nà ìpínlẹ̀ Anambra pè fún ìrànlọ́wọ́ fún ètò ìlera alábọ́ọ́dé
Kọmíṣọ́nà fún ìlera ti ìpínlẹ̀ Anambra , Dókítà Afam Obidike,ti rọ àwọn ènìyàn,agbègbè láti ṣe àtìlẹyìn fún ìjọba láti ṣe ìmúdúró ètò ìlera tó múnádóko àti èyí tó ṣeé gbára lé,tí yóò sì wà…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Kaduna Ti Bẹ̀rẹ̀ Ìwòsàn Ọ̀fẹ́
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Kaduna ti bẹ̀rẹ̀ ìwòsàn ọ̀fẹ́ fún àwọn ọmọ Ìpínlẹ̀ náà, èyí tí yóò wáyé fún ọ̀sẹ̀ kan gbáko.
Alákòsóo Ètò Ìlera ní Ìpínlẹ̀ náà, Dókítà Amina Mohammed-Baloni sọ wípé ìwòsàn…
Igbákejì Ààrẹ Sí Gbọ̀ngàn Ilé Ìwòsàn Ìgbàlódé Ní Ìpínlẹ̀ Ogun
Igbákejì Ààrẹ orílẹ̀ Nàìjíríà, Ọ̀jọ̀gbọ́n Yẹmi Osibajo ti sọ ilé ìwòsàn tí ó gbà tó bẹ́ẹ̀dì ọgọ́rùn-ún fún ìtọ́jú àwọn Obìnrin àti Ọmọdé di lílò ní ìlú Ipẹru-Rẹmọ, Ìpínlẹ̀ Ogun
Igbákejì Àar̀ẹ…
Ènìyàn Pàtàkì, Ọmọ Bíbí Ìpínlẹ̀ Bauchi Yóò Jẹ Anfààní Ìlera Ọ̀fẹ
Àjọ Bauchi State Health Contributory Management Agency, BASHCMA, sọ pé àwọn tí kọ orúkọ àwọn ènìyàn pàtàkì, ọmọ bíbí Ìpínlẹ̀ Bauchi ti yóò jẹ ànfààní Ìlera ọ̀fẹ́ sílẹ̀.
Àwọn tí yóò jẹ ànfààní yi ní wọ́n sà kà kiri…
Ẹ́ Tiwá-lẹ́yìn Fún Ètò Ìlera Tó Múná Dóko – Kọmisana Anambra
Kọmisana fún ètò ìlera ní ìpínlẹ̀ Anambra, Dókítà Afam Obidike tí ke sí gbogbo aráàlú látí ṣé àtìlẹ́yìn fún ìjọba ìpínlẹ̀ náà látí ṣé àṣeyọrí lórí ètò ìlera tó múná dóko pẹ̀lú owó kékeré fún gbogbo ènìyàn.
Dókítà Obidike bẹ̀bẹ̀ èyí…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Yobe Dá Ilé Ìwòsàn Alábọ́dé Ogóje Sílẹ̀
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Yobe sọ wípé òun ti dá àwọn llé Ìwòsàn alábọ́dé tí ó tó ogóje sílẹ̀ ní Ìpínlẹ̀ náà lójúnà àti pèsè ètò ìlera tí ó péye fún àwọn ará ìlú.
Alhaji Muhammed Mamman, tí ó jẹ́…
Àjọ Adójútòfò Pèsè Ohun Èlò Ìlera Fún Àwọn Ilé Ìwòsàn Ní Ìpínlẹ̀ Kano
Kò dín ní Ilé ìwòsàn mẹ́ẹ̀rin ní ìpínlẹ̀ Kano tí ó ti jẹ ànfààní ìpèsè àwọn ohun èlò ìlera láti ọwọ́ àjọ tí ó ń mójútó ìsẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì, lójúnà àti se ìgúnpá fún àwọn tí ó lùgbàdì…
Aya Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kebbi Pè Fún Pípèsè Ohun Èlò Tí Ó Péye Fún Ìtọ́jú Àrùn Jẹjẹrẹ
Arábìnrín àkọ́kọ́ ní ìpínlẹ̀ Kẹbbi, Ọ̀mọ̀wé Zainab Shinkafi Bagugu ti ké sí àwọn aládàníi àti Ìjọba fún ìpèsè ètò ìwòsàn tí ó peregedé fún ìtọ́jú àrùn jẹjẹrẹ.
Arábìnrin Bagudu sọ ọ̀rọ̀ náà ní…
Ilé Ìwòsàn Aládáni Se Iṣẹ́ Abẹ ‘Laparoscope’ Àkọkọ́ Ní Àseyege Ní Ìpínlẹ̀ Yobe
Ilé Ìwòsàn Aládáni ti Ayaji Medical and Diagnostic Centre ní ìlú Gashua, ti se iṣẹ́ abẹ 'Laparoscope' àkọ́kọ́ ní àṣeyọrí ni Ìpínlẹ̀ Yobe.
Laparoscopy jẹ́ ọ̀nà kan tí wọ́n fi ń se iṣẹ́ abẹ nípa lílo ohun èlò iṣẹ́ abẹ sí ẹ̀yà ara…