Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌLERA
This is a category for health news
Ẹ jáwọ́ nínú dídábẹ́ fún àwọn ọmọbìnrin-Oluwakemi Olawoyin
Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ pẹ̀lú àjọsepọ̀ ajọ Hacey Health Initiative ló se àgbékalẹ̀ ìdánilẹ̀ẹ̀kọ́ fún awọn akọroyin ni ipinlẹ Ọ̀yọ́ lori ipa ti wọn le ko lati fi opin si ìdábẹ́ fun awọn ọmọbinrin (Female Genital Mutilation, FGM)…
Àjọ tẹ̀síwájú lórí ìṣètọ́jú ìgbẹ́ gbuuru èwe Ní Sókótó, Kánò
Láti pa ìgbé gbuuru èwe kúrò ní Àríwá Nàìjíríà, Ẹgbẹ́ tí kìí ṣe tìjọba, Wellbeing Foundation Africa sọ pé, ó ti ṣe àṣeyọrí ní ìpele àkọ́kọ́ ti 'Scaling Up Zinc and Low-Osmolarity Oral Rehydration Solution' tí wọ́n…
Ìwọ̀n kan Àjẹsára HPV Tó Fún Ìdáábòbò Ààrùn jẹjẹrẹ- Àwọn amòye
Àjẹsára apillomavirus ìwọ̀n kán le dènà HPV, àti pé ìwọ̀n náà jẹ́ àfiwé ìṣètò ìwọ̀n lílo méjì,gẹ́gẹ́ bí ìwádìí tuntun ṣe ríi.
Eyi jẹ ni ibamu si Ẹgbẹ Igbimọ to n pese Imọran Ilera lori ajẹsara ti ajọ to n risi…
COVID-19: Ìjọba Nàìjíríà Gba Abẹ́rẹ́ Àjẹsára Tí Ó Lé Ní Milionu Mẹ́ta
Ìjọba Nàìjíríà ti gba abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 Johnson ati Johnson tí ó lé ní miliọnu mẹ́ta láti ọwọ́ ìjọba Italy
Olùdarí àgbà fún Ilé-iṣẹ́ ìdàgbàsókè ìlera orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Dokita Faisal Shuaib,…
Ààrùn rọpárọsẹ̀:Ìpínlẹ̀ Èkó, LASG bẹ̀rẹ̀ Ìpolongo àjẹsára
Ìpínlẹ̀ Èkó ti bẹ̀rẹ̀ ìpolongo abẹrẹẹ àjẹsára ajẹ́jẹ̀ẹ́sí ti ààrùn rọpárọsẹ̀ ìpele kìnní àti ìkejì ti ọdún 2022 ní òpin ọ̀sẹ̀ yìí.
Akọwe gbogbogboo, ajọ itọju ilera akọkọ ti ipinlẹ Eko, Dokita Ibrahim A. Mustafa, sọ eyi ninu…
WHD: WHO ńpè fún ìdáábòbò tó péye fún Ìlera ọmọnìyàn
Àjo Àgbáyé (WHO) ti pè fún ìgbésè tó nípa láti ọ̀dọ àwọn olùdarí àti gbogbo enìyàn fún ìtọ́jú àti ìdáábòbò ìlera àti díndín aáwọ̀ ojú-ọjọ́ kù gẹ́gẹ́ bí apákan ìpolongo “Ayé wa, ìlera wa” tí ń…
NMA ṣèdárò lórí ikú arábìnrin Dókítà tí ó pàdánù ẹ̀mí ẹ̀ nínú ìkọlù ọkọ̀ ojú…
Ààrẹ Ẹgbẹ́ Ìṣègùn Nàìjíríà (NMA), Ọ̀jọ̀gbọ́n Innocent Ujah, sọ pé gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ ìṣègùn àti ehín lábẹ́ àbójútó NMA ni ó banújẹ́ lórí iṣẹlẹ aburú, tí ó tún bani lẹ̀rù tí ó fa ikú Dókítà Chinelo Nwando, ẹni tí wọ́n pa nínú ìkọlù…
Nàìjíríà yóò ṣagbátẹrù àpérò Ìyípadà PHC Ní ìlú Àbújá
Ìjọba Nàìjíríà nípasẹ̀ ilé-iṣẹ́ tó ń mójútó ìdàgbàsókè ètò ìlera alákọ́bẹ̀rẹ̀ (NPHCDA), ti ṣètò láti ṣagbátẹrù àpérò Ìtọ́jú Ìlera ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀.
Pataki Apero naa ni lati ṣe ifilọlẹ eto tuntun lati yi…
Covid-19: Àwọn ènìyàn mẹ́tàlélọ́gbọ̀n míràn tún ti ní ààrùn corona
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ ede Naijiria , Nigeria Centre for Disease Control (NCDC) ti kede pe awọn ènìyàn mẹ́tàlélọ́gbọ̀n míràn tún ti ní ààrùn coronalorilẹ ede Naijiria.
Ajọ naa kede pe ipinlẹ Marun un ni…
Awon eniyan metale-logojo miran tun ti ni aarun corona
Ile ise to n mojuto ajakale aarun ni orile-ede Naiiria (NCDC) ,so pe awon eniyan metale-logojo miran lo tun ti ko aarun corona jakejado orile-ede bayii o.
Awon eniyan won yii si jeyo ni awon ipinle metala : Lagos ti o ni eyi ti o poju…