Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌLERA
This is a category for health news
Àìsàn Inú Àti Ọ̀fun: Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ti Pàdánù Àwọn Ènìyàn Tó Lẹ Ni Ọgọrùn Látàrí Abẹ́rẹ́…
Àjọ tó n mójú tó ètò ìlera ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà NCDC, sọ wí pé àwọn ènìyàn tó lẹ́ ni ọgọrùn ni o ti pàdánù emi wọn látàrí àìsàn to n ba inú àti Ọ̀fun jà èyí to n ṣẹlẹ báyìí nì Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Àjọ NCDC sọ èyí di mímọ̀ nígbà tí wọn…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ebonyi Gbégbá Orókè Nípa Ètò Ìlera- Akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ Gbósùbà Fún Ìjọba
Alága Ẹgbẹ́ àwọn elétò ìlera ẹka ti ìpínlẹ̀ Ebonyi, Chetachi Usulor ti gbósùbà fún gómìnà Ìpínlẹ̀ Ebonyi, Francis Nwifuru látàrí akitiyan rẹ̀ lórí ìdàgbàsókè ètò ìlera ní ìpínlẹ̀ náà
Usulor lu…
Ẹ Wà Ní Ojú Ni Alákàn Fi Ń Sọ́rí Gẹ́gẹ́ Bí Àjọ NCDC Se Sàwárí Àrùn Ibà Lassa
Àjọ NCDC ti sàwárí àrùn ibà Lassa láti ara akọhṣẹ́mọṣẹ́ oníṣègùn òyìnbó ẹni ọdún mọ́kànlélọgbọun kan tí ó ṣẹ̀sẹ́ dé láti Orilẹ-ede United Kingdom
Dokita Jide Idris ni ó síṣọ lóju ọrọ naa nígbà ti o n…
Ọ̀fẹ́ Ní Ìtọ́jú Àrùn HIV Ní Ilé Ìwòsàn Ìjọba Gbogbo- Àjọ NACA Fìdí Ọ̀rọ̀ Múlẹ̀
Àjọ NACA sàpèjúwe ìròyìn kan tí ó ń jà káàkiri orí ẹ̀rọ ayélujára gẹ́gẹ́ bí ìròyìn òfegé èyí tí ó sọ pé ìjọba tí yọwọ́ ìrànwọ́ rẹ̀ kúrò lórí ìtọ́jú àìsàn HIV
Adarí àpapọ̀ fún àjọ…
Alága Ìjọba Ìbílẹ̀ Se Ìfilọ́lẹ̀ Àtúnṣe Ilé Ìwòsàn Alábódé Ní Ìlú Omu-Aran
Alága ìjọba Ìbílẹ̀ Ìfẹ́lódùn, Ìpínlẹ̀ Kwara, Ọ̀gbẹ́ni Abdulazeez Yakubu ti se ìfilọ́lẹ̀ ní Ọjọ́rú láti se àtúnṣe ilé ìwòsàn alábọ́dé tí ó wà ní Ofe Aran, ní Ilu Omu-Aran
Nígbà tí ó ń sọ̀rọ̀,…
Ìgbáyégbádùn Àwọn Dókítà Onímọ̀ Ìsègùn Òyìnbó Se Pàtàkì- Ẹgbẹ́ Dókítà Ẹka Ti…
Ẹgbẹ́ Àwọn Dókítà Onímọ̀-Ìsègùn Òyìnbó ẹka ti Abuja ti pàrọwà sí ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin láti bu ojú àánú wo ọ̀rọ̀ ìgbáyégbádùn àwọn ọmọ ẹgbẹ́ náà
Dókítà Emeka Ayogu tí ó jẹ́ alága ẹgbẹ́ náà ní ẹka…
Ìjọba Àpapọ̀ Buwólu Òbítíbitì Owó Fún Ìdàgbàsókè Ètò Ìlera Ní Orílẹ̀-èdè…
Ìjọba Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti gbé iṣẹ́ fún àwọn agbáṣẹse tí yóò pèsè ohun èlò ìlera pẹ̀lú bíbuwọ́lu bílíọ̀nù mẹ́wàá lé ọwọ́ mẹ́ta láti fi ra àwọn ohun èlò náà
Nígbà tí ó ń ba àwọn akọ̀ròyìn…
Òmìnira Àwọn Aláìsàn Se Pàtàkì Ní Ilé Ìwòsàn Gbogbo- Àjọ Kan Ti kì í Se Ti Ìjọba…
Àjọ Disney Foundation ti pàrọwà ní ọjọ́ Àbámẹ́ta sí ọmọ Naijiria láti sàfihàn títẹ ẹ̀tọ́ wọn lójú mọ́lẹ̀ nígbà tí wọ́n bá wà ní ilé ìwòsàn fún ìtọ́jú
Ọ̀gbẹ́ni Martins Nwanne pe ìpé náà níbi ayẹyẹ…
Ni Ìpínlẹ̀ Oyo Ṣe Ìtọ́jú Ọfẹ Fún Àwọn Ọmọ Ilé Ìwé Alakobere.
Bí ètò ìtọjú ìlera ṣe di ohun inira fún ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn ni Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà báyìí pàápàá jùlọ àwọn ọmọdé, Ìpínlẹ̀ Oyo ti ṣe Ìrànlọ́wọ́ fún àwọn ọmọdé nípa ètò ìtọ́jú ìlera ọfẹ.
Àjọ àgbáyé fún ètò ìlera sọ wí pé òpòlopò àwọn ènìyàn,…
Àjọ UNFPA Gbé Àwọn Ohun Èlò Ètò Ìfẹ̀tọ̀sọ́mọíbí Fún Ìjọba Ìpínlẹ̀ Kano.
Àjọ tí wọn pẹ ni United Nations Population Fún (UNFPA) ni ọjọ̀bọ̀ ti fá àwọn ohun èlò fún ètò Ifetosomobibi fún ìjọba ìpínlẹ̀ Kano.
Dọ́kítà Audu Alayande, tó jẹ aṣojú fún Àjọ náà sọ wí pé oun mú àwọn elo náà wà fún lílò àti àlàáfíà àwọn…