Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌLERA
This is a category for health news
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kwara Fi Ẹ̀dùn Ọkàn Hàn Látàrí Bí Àsìlò Òògùn Se Gbilẹ̀ Láàrin…
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kwara, Ààrin Gbìngbìn Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, AbdulRahaman AbdulRasaq ti fi ẹ̀dùn ọkàn hàn látàrí bí àsìlò òògùn se gbalé-gboko láàrin àwọn ọ̀dọ́ ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà
…
Wọ́n Dá Oníṣègùn Òyìnbó Ọgọ́rùn-ún Dúró Ní Ilé-ìwòsan Orílẹ̀-èdè Kenya
Ilé ìwòsàn ni ilu Nairobi tí se olú ìlú Kenya ti dá ọgọrùn Oníṣègùn Oyinbo to kópa nínu ìfẹ̀hónúhàn apapọ to n lọ lọwọ fún bí osu kan bayi duro, alabojuto sọ eyi ni ọjọ Isẹgun.
Ilé ìwòsàn Kenyatta University Referral sọ pé awọn…
Àjọ NACA Pé Fún Ìlera Pípé Lásìkò Ọdún Ìtùnú Àwẹ̀
Gẹ́gẹ́ bí a ti mọ wí pé àwọn ẹlẹṣin Mùsùlùmí lágbayé n ṣe ajoyọ ọdún ìtùnú awé, àjọ tó n mójú tó ọ̀rọ̀ àìsàn Kògbóògùn (NACA) rọ àwọn ènìyàn láti rí wí pé wọn ṣe àkíyèsí ará wọn lásìkò náà.
Adarí Àgbà Pátápátá Fún àjọ NACA, Dọ́kita…
Àjọ NCDC Ni Àwon Yóò Ṣe Iwadii Àisìán Àjèjì Tó Sẹ́yọ Ni Ìpínlẹ̀ Sokoto.
Àjọ tó n mójú tó ọ̀rọ̀ ìlera àti àìsàn ni Orílè-èdè Nàìjíríà NCDC, sọ wí pé àwọn n ṣe ìwádìí lọwọlọwọ nípa àìsàn àjèjì tó kọlù wọ́ọ̀dù mẹfa ni ìpínlẹ̀ Sokoto
Ọ̀gá àgbà pátápátá fún àjọ NCDC , Dọ́kítà Jide Idris sọ èyí di mímọ wí pé àjọ…
Àìsàn Ikọ́ Féére Gbalé-Gboko Ní Ìpínlẹ̀ Benue, Ó Wà Ní Ipò Kẹfà Nínú Ìpínlẹ̀ Tí…
Kọmísọ́nà Fún Ètò Ìlera Àti Ìrànlọ́wọ́ Ọmọnìyàn ní Ìpínlẹ̀ Benue, Dókítà Yanmar Ortese ti síṣọ lójú ọ̀rọ̀ pé, Ìpínlẹ̀ Benue wà ní ipò kẹfà nínú àwọn Ìpínlẹ̀ tí àìsàn ikọ́ féére ń bá fínra jùlọ èyí…
Ìwòsàn Ọ̀fẹ́ Ti Bẹ̀rẹ̀ Ní Pẹrẹwu Ní Ìpínlẹ̀ Abia
Ọmọ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kan tí ó fi ìlú Amẹ́ríkà se ibùjòkó ti se agbátẹrù ìwòsàn ọ̀fẹ́ èyí tí ó ní àfojúsùn ìtọ́jú ènìyàn tí ó tó ẹgbẹ̀rún méje tí ó ní orísìírísìí ìpèníjà àìsàn…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Gbé Ìgbésẹ̀ Akin Láti Fi Òpin Sí Síṣe Ìgbọ̀nsẹ̀ Sí Ìta Gbangba
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, lábẹ́ ìdaŕi Gómìnà Seyi Makinde ti fi ìgbáradì rẹ̀ léde lójúnà àti fi òpin sí síṣe ìgbọ̀nsẹ̀ sí ìta gbangba jákè-jádò ìpínlẹ̀ náà
Alákòóso àpapọ̀ fún ìpèsè omi àti…
Àyájọ́ Ìlera N’àgbáyé : Àjọ WHO Pè Fún Ètò Ìlera Tí Ó Múná Dóko Fún Mùtú-mùwà
Àjọ WHO pè fún àgbékalẹ̀ ètò ìlera tí ó péye fún tolórí-tẹlẹ́mù, Ó wá késí Orílẹ̀-èdè àgbáyé láti fi ọwọ́sowọ́pọ̀ fún ètò ìlera tí ó dára fún ìgbáyégbádùn ọmọnìyàn
Àjọ WHO pàrọwà síwájú…
Àjọ NIMR Sẹ Àfihàn Ọ̀nà Abayọ Gbógì Láti Ṣe Ìdàgbàsókè Fún Fí Fí Ẹ̀jẹ̀ Sílẹ.
Àjọ tó n ṣe ìwádìí nípa fífi ẹ̀jẹ̀ sílẹ ni Orílè-èdè Nàìjíríà NIMR, ti ṣe àfihàn ọ̀nà abayọ sí fi fí ẹ̀jẹ̀ sílẹ nípa ẹ̀rọ ìgbàlódé.
Ọ̀mọ̀wé Babatunde Salako tó jẹ Adari àgbà pátápátá fún Àjọ náà sọ wí pé èro ìgbàlódé náà wà fún ọnà abayọ…
Ìpínlẹ̀ Kwara: Àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ Ilé Ìwé Fásítì Ìlọrin Pèsè Ògùn, Iná Mọ̀nàmọ́ná Fún Àwọn Ilé Ìwòsàn…
Àwọn Akékòó nípa ètò ìlera ni fásítì ti ìlú Ilorin, tí pèsè, Ògùn, àwọn ohun èlò iranlọwọ àti iná Mọ̀nàmọ́ná Fún ilé ìwòsàn kàkàkíri ìpínlẹ̀ Kwara.
Àwọn Akékòó náà sọ wí pé àwọn tun ṣe àwọn ilé ìwòsàn àti omi tí wọn ti pa tì.
Ọ̀mọ̀wé…