Browsing Category
Ìròyìn Àyíká
Ipinlẹ Anambra Gbé Ìgbésẹ Akínkanjú Nípa Títún Àyíká Àti Bèbè Omi Ṣe.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Anambra pẹ̀lú àjọsọpọ̀ - "Initiative for Agulu Development" ní ọnà láti ṣe ìmọ́tótó sì àwọn agbègbè ti omi wà àti àwọn àyíká rẹ àti ni ọ̀nà láti jẹ́ kí ẹ̀gbin omi dínkù, wọn ti ṣètò ìmọ́tótó ní gbogbo bèbè omi àti ètò…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Kwara Ri Asia Iṣọkan
Àárín gbùngbùn ipinlẹ Kwara ti ri ásíà iṣọkan oní àádọ̀rin Mítà ní gíga ti gómìnà AbdulRahman AbdulRazaq pé ìtúmọ̀ rẹ̀ ní "Iṣọkan àpapọ̀" - “national unity", àjọsọpọ Irinajo wà àti èròngbà wà gẹ́gẹ́ bí ènìyàn.
Ní ibi ìpàdé…
Ìjọba Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ti Jẹ̀jẹ́ Pé Àwọn Yóò Tún Ọ̀nà Benin-Sapele Se
Ìjọba Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti sèlérí pé àwọn yóò tún Ọ̀nà Benin-Sapele tó ti bajẹ tó wà ní ìpínlẹ̀ Edo, gúsù Nàìjíríà ṣe ní kíámọ́sá.
Mínísítà ipinlẹ fún iṣẹ ode, Bello Goronyo ló ṣe ileri yìí látàrí ẹ̀bẹ̀ láti ọdọ àjọ tl…
Mínísítà Múlele Lórí Ìwúlò Àjọṣepọ̀ Ilẹ̀ Òkéere Fún Ìtèsíwájú Ẹ̀ka Ètò Ìwakùsà
Ìgbákejì pataki nípa iroyin sì Mínísítà ìtèsíwájú àwọn ohun alumọni ilẹ̀,Segun Tomori ló gbé eleyi síta.
Dókítà Alake sọ pàtàkì ojuse ìwakùsà nípa ti ìlànà agbaye ní ti àjọ Organisation for Economic Cooperation and…
Orílẹ̀-èdè Nàmíbíà Ri Àrídájú Àjàkálẹ̀ Àìsàn Ẹṣin Adúláwọ̀
Ẹ̀ka tó wà fún ìtọjú àwọn ẹranko orílẹ̀-èdè Nàmíbíà ti kéde àjàkálẹ̀ àìsàn ẹṣín ilẹ̀ Adúláwọ̀ - "African horse sickness", wọ́n sì ti kófí àìsàn nàá lára márùndínlọ́gbọ̀n ènìyàn níbi ẹ̀ka ti ń mójú tó àwọn ẹranko ní agbègbè Otjinene,…
Ìjà Ìgboro Agbègbè Sọ Mẹ́ẹ̀dógún Ènìyàn Dolóògbé, Mẹ́rìndínlógún Farapa Ní Gúsù Sudan
Ó kéré tán ènìyàn mẹ́ẹ̀dógún ti dágbére f'áyé tí mérìndínlógún míràn sì tún farapa nínú àwọn ikọ̀lù ìjà Ìgboro agbègbè ní Tonj South County, Warrap State, Ariwa South Sudan, ẹnìkan sọ èyí ní ọjó Ẹtì.
Kọmísọ́nà Tonj South County, Ring Deng…
Ìdìbò Ọdún 2027: Ẹgbẹ́ Òṣèlú Labour Party Kòní Darapọ̀ Mọ́ Ẹgbẹ́ Mìíràn
Ẹgbẹ́ Òṣèlú Labour Party ti sọ pé àwọn koni darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ míràn ninu ìbò gbogbogbòò ọdún 2027.
Èyí jẹ ọkan lára kókó méjìlá àlàkalẹ̀ ìpinnu níbi Ìpàdé National Executive Council (NEC) ti wọn ṣe ní ọjó Ẹtì ní ìlú Abuja.
Nigba ti o ń…
Àjọ NUPEC Gbáradì Láti Dá Ààbò Bo Àwọn Ibi Ìwakùsà
Àjọ National Unity and Peace Corps, NUPEC sọ pé àwọn ti ṣetán ju àtẹ̀yìn wá lọ láti fi ààbò bo àwọn ibi Ìwakùsà káàkiri orílẹ̀-èdè yìí látàrí ìwé àbádòfin Ìfilọ́lẹ̀ tó de àjọ náà ti wọ́n yóò buwọ́lù.
Ọ̀gá àgbà patapata àjọ náà,…
Ìṣòro Ojú Ọjọ́: Ààrẹ Gba Àwọn Olórí Àgbáyé Nímọ̀ràn Láti Wà Ní Ìṣọ̀kan
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu ti gba àwọn adari agbaye nímọ̀ràn láti wà ní isokan, ní emi ìgboyà àti kí wọn ní ẹ̀mí ifaraji láti ṣàkóso ìṣòro oju ọjó lágbáyé tó n buru síi.
Ààrẹ sọ eyi ní ọjó ojoru nibi Ipade apero láti ori ero…
Mínísítà Àṣà Kí Àlàáfín Tuntun Ti Ìlú Ọ̀yọ́ Kú Oríire
Mínísita orílè-èdè yìí fún àṣà, iṣẹ, Ìrìn-àjò òun igbafe àti ọgbọ́n àtinúdá ọrọ̀ ajé, Hannatu Musawa ti kí Àlàáfín tuntun ti Ìlú Ọ̀yọ́, Ọba Abimbola Akeem Owoade, kú oríire, ti ìgorí ìtẹ́ baba rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí Aláàfin…