Browsing Category
Ìròyìn Àyíká
Ilé Asòfi Èkó Ti Pàsẹ Kí Ìjọba Fòpin Sí Isé Ile Wíwó Tó Ń Lọ Lọ́wọ́ Ní Agbègbè Makòko
Ilé Igbimo Asofin Ìpínlè Èkó ti pàse kí ìjoba fòpin sí isé Ile wíwó tó n lo lówó ní agbègbè Makòko légbe odo Òsà ní Ìpínlè naa.
Asòfin Noheem Adams tí ó jé Alága Ìgbìmò tèékótó tí Olùdarí Ilé Ìgbìmò Asòfin náà, Asòfin Mudashiru…
Abuja Ní Àádọ̀ta Ọdún: Wike Bẹ́rî Fún Àyípadà FCT
Mínísítà Olu ilu Naijiria, Abuja, FCT, ọgbẹni Nyesom Wike ti gboriyin fún idagbasoke àti ayipada ìlú náà lẹ́yìn àbẹwò rẹ sì àwọn àkànṣe iṣẹ ní ọjó Iṣẹgun ní ọnà láti sami sì ọdún aadọta ìlú Abuja.
Ó sojú abẹ niko pé, ìjọba ààrẹ…
Nàìjíríà Ṣetán Láti Ṣàgbékalẹ̀ Ohun Alùmọ́nì Agbára Nípasẹ̀ Àjọṣepọ̀ Àwọn Orílẹ̀-èdè Ilẹ̀ Adúláwọ̀
Ààrẹ Tinubu sọ pé orílẹ-èdè Nàìjíríà ti ṣetan láti darapọ̀ mọ́ àwọn orílẹ-èdè ilẹ̀ Adúláwọ̀ àti alatilẹyin agbaye pẹlu àwọn aladani láti sàgbékalẹ̀ ohùn alumọni agbara to rọrùn láti ní alápapọ̀ to mọ́ toto.
Ààre Nàìjíríà sọ…
Ìyàwó Ààrẹ Nàìjíríà Rọ Ọmọ Orílẹ-èdè Yìí Látì Tẹ́wọ́ Gba Ohun Àlùmọ́nì Agbára
Ìyàwó Ààrẹ Orílẹ-èdè yìí ti rọ àwọn ọmọ orílẹ-èdè yìí látì tẹwọ gba ohun alumọni agbara fún àyíká tó mọ́ tótó.
Ó sọ èyí nibi ọrọ rẹ láti sami sì ayeye ọjọ ayika to mọ́ toto agbaye ọdún 2026.
Arabinrin akọkọ rọ gbogbo ọmọ Naijiria…
Makinde Ṣèlérí Láti Ṣe Àfọ̀mọ́ Àṣà To Níí Ṣe Pẹ̀lú Àyíká Àti Àmójútó Ìdọ̀tí: Ó Búra Fún Aderinto…
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti ṣèlérí
pé ìṣèjọba rẹ̀ yóò dojú ìjà kọ àwọn àṣà eléyìí tí àwùjọ ti jinlẹ̀ nínú rẹ̀ lórí ayíká àti àmójútó ìdọ̀tí ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, fún ànfàní gbogbo ará ìlú.
Gómìnà ló sísọ lójú ọ̀rọ̀ yìí lásìkò tó n…
Ipinlẹ Anambra Gbé Ìgbésẹ Akínkanjú Nípa Títún Àyíká Àti Bèbè Omi Ṣe.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Anambra pẹ̀lú àjọsọpọ̀ - "Initiative for Agulu Development" ní ọnà láti ṣe ìmọ́tótó sì àwọn agbègbè ti omi wà àti àwọn àyíká rẹ àti ni ọ̀nà láti jẹ́ kí ẹ̀gbin omi dínkù, wọn ti ṣètò ìmọ́tótó ní gbogbo bèbè omi àti ètò…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Kwara Ri Asia Iṣọkan
Àárín gbùngbùn ipinlẹ Kwara ti ri ásíà iṣọkan oní àádọ̀rin Mítà ní gíga ti gómìnà AbdulRahman AbdulRazaq pé ìtúmọ̀ rẹ̀ ní "Iṣọkan àpapọ̀" - “national unity", àjọsọpọ Irinajo wà àti èròngbà wà gẹ́gẹ́ bí ènìyàn.
Ní ibi ìpàdé…
Ìjọba Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ti Jẹ̀jẹ́ Pé Àwọn Yóò Tún Ọ̀nà Benin-Sapele Se
Ìjọba Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti sèlérí pé àwọn yóò tún Ọ̀nà Benin-Sapele tó ti bajẹ tó wà ní ìpínlẹ̀ Edo, gúsù Nàìjíríà ṣe ní kíámọ́sá.
Mínísítà ipinlẹ fún iṣẹ ode, Bello Goronyo ló ṣe ileri yìí látàrí ẹ̀bẹ̀ láti ọdọ àjọ tl…
Mínísítà Múlele Lórí Ìwúlò Àjọṣepọ̀ Ilẹ̀ Òkéere Fún Ìtèsíwájú Ẹ̀ka Ètò Ìwakùsà
Ìgbákejì pataki nípa iroyin sì Mínísítà ìtèsíwájú àwọn ohun alumọni ilẹ̀,Segun Tomori ló gbé eleyi síta.
Dókítà Alake sọ pàtàkì ojuse ìwakùsà nípa ti ìlànà agbaye ní ti àjọ Organisation for Economic Cooperation and…
Orílẹ̀-èdè Nàmíbíà Ri Àrídájú Àjàkálẹ̀ Àìsàn Ẹṣin Adúláwọ̀
Ẹ̀ka tó wà fún ìtọjú àwọn ẹranko orílẹ̀-èdè Nàmíbíà ti kéde àjàkálẹ̀ àìsàn ẹṣín ilẹ̀ Adúláwọ̀ - "African horse sickness", wọ́n sì ti kófí àìsàn nàá lára márùndínlọ́gbọ̀n ènìyàn níbi ẹ̀ka ti ń mójú tó àwọn ẹranko ní agbègbè Otjinene,…