Browsing Category
Ìròyìn Àyíká
Oúnjẹ yanturu: Asọ́bodè Nàìjíríà Dá Ọ̀pọ̀ Ọkọ̀ Tó Ń Kó Oúnjẹ Lọ Ìlú Ibòmíràn Dúró
Ní ọ̀nà lati jẹ ki ounje sùnwábọ̀ ni orile-ede yii, àjọ awọn Asọ́bodè ti kéde pé àwọn ti da ọkọ̀ nla ti oye rẹ jẹ ọgọfa duro lọ́nà to n ko ounjẹ orisirisii lọ sí gbogbo agbegbe orílẹ̀-èdè Naijiria.
Olórí àwọn Asọ́bodè Nàìjíríà, ọgbẹni…
Ọjọ́ Àyájọ́ Àwọn Obìnrin Lágbáyé: Mínísítà Gbóríyìn Fún Àwọn Obìnrin
Mínísítà orile-ede Naijiria ni eka ti aṣa, ẹwà ọnà ati ọgbọn atinuda ọrọ ajé, Hannatu Musawa ti ki awon obinrin ni ẹka náà ku oriire ayajọ awọn obinrin lagbaye.
Musawa fi ìdùnnú àti ìkíni rẹ ransẹ sí gbogbo àwọn obìnrin olorire…
Ilé iṣé Ìjọba Ti Ó Ń Mójú Ìdọ̀tí Yóò Gba Ìbáwí: Ijoba Ìpínlẹ̀ Kwara.
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Kwara ti ṣe ìkìlọ nla fún àwọn ilé iṣé to n mójú tó ìdọ̀tí lati ṣe iṣẹ wọn bí iṣẹ
Mínísítà fún ọ̀rọ̀ agbègbè Malam Shehu Ndanusa ló ṣe ìkìlọ náà lákòkóò to n bá wọn se ìpàdé ní ìlú Ilorin.
Ó ní isé wọn ní lati rí wí pé…
FCTA fa ibùsọ̀ ọkọ̀ Area 1 lé ẹgbẹ́ lọ́wọ́
Ibùsọ̀ ọkọ̀ ìlúmọ̀ọ́ká ti Area 1, ní Garki, Olú ìlú Nàìjíríà, Abuja ti fa ìṣàkóso àti ìṣiṣẹ́ ibùsọ̀ ọkọ̀ lé ẹgbẹ́ onímọ́tò lọ́wọ́.
Adari iṣẹ, ti iṣakoso ise lilọ bibibọ oju ọna, DRTS, Deborah Osho, sọ eleyi lasiko…
Àtúnṣe Gbogbo Ọ̀nà Ló Jẹ́wa Lógún – David Umahi
Mínísítà fún àkànṣe iṣẹ orílẹ̀-èdè yìí, David Umahi ti sọ pé àtúnṣe gbogbo ọ̀nà jakejado ilẹ̀ yi ló jẹ àwọn lógún.
" Gbogbo nǹkan ni ọ̀nà jẹ́, tí ẹ bá tú ọ̀nà se, ètò ààbò, ọ̀gbìn, ẹ̀kọ́, ọrọ̀ ajé àti ayọ̀ àwọn ènìyàn ni ẹ ti tún…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Èkó Se Kóríyá Fún Àjọ Akólẹ̀-kódọ̀tí
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó, Babajide Sanwo-Olu ti buwọ́lu àlékún owó tí ó jẹ́ ti ìparí ọdún fún àjọ akólẹ̀-kódọ̀tí ti ìpínlẹ̀ Èkó, LAWMA.
Alákòóso Àjọ LAWMA, Ọ̀mọ̀wé Muyiwa Gbadegẹsin sísọ lójú ọ̀rọ̀…
Ìjọba àpapọ̀ Fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú CSO lórí ìjẹ́rìísí àti ìmọ́gara iṣẹ́ àkànṣe omi,ìmọ́…
Ilé-iṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ tó ń mójútó orísun Omi àti Ìmọ́ tótó ti ṣàlàyé ipa pàtàkì tí Ẹgbẹ́ Àwùjọ Ìlú, (CSOs) ń kó nínú Ìjẹ́rìísí àti Ìmọ́gaara lórí àwọn iṣẹ́ àkànṣe omi àti ìmọ́tótó jákèjádò…
Ààrẹ Tinubu Buwọ́lu Àtúnṣe Ọ̀nà Ọ̀tàlélúgba Jákèjádò Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà
Ààrẹ Tinubu ti buwọ́lu àtúnṣe kíámọ́sá ọ̀nà Ọ̀tàlélúgba jákèjádò gbogbo ìpínlẹ̀ Orílẹ̀-èdè yí àti olú ìlú Nàìjíríà.
Owo àtúnṣe kíámọ́sá ti wọ́n rí gbà jẹ ẹ̀tàadínlógún-lé-nígba bílíọ̀nù náírà lati se ọ̀nà náà ni ìgbà tí ọ̀gbẹlẹ̀ bá…
Kò sí ẹni tí ó fara pa níbi ilé tí ó dàẃo ní Ìlú Eko- NEMA
Àjọ tó ń rísí ìṣàkóso pàjáwìrì lórílẹ̀-èdè, NEMA, ti fìdí rẹ̀ múlẹ̀ ní ọjọ́ Àbámẹ́ta pé kò sí ẹni tí ó fara pa níbi ilé alájà mẹ́ta tí ó dàẃo ní òpópónà Ikpoh, ní Surulere, ní ìpínlẹ̀ Eko, Iwọ̀…
Òjò àrọ̀ọ̀dá fa omíyalé ní Makurdi
Àwọn olùgbé ní Makurdi, ìpínlẹ̀ Benue, Aringbungbun Nàìjíríà, àti àwọn agbègbè rẹ̀ ti wà nínú pákáleke bí omíyalé ṣe ṣẹlẹ̀ ní àwọn apá kan ìlú náà nítorí òjò àrọ̀ọ̀dá tó rọ̀ fún bíi wákàtí…