Take a fresh look at your lifestyle.
Election
Browsing Category

ÌRÒYÌN ÀṢÀ ÀTI ÌṢE YORÙBÁ

This is a category for culture and life news

Ìgbìmọ̀ Ọmọ bíbí Ilẹ̀ Ìbàdàn ti bẹ̀rẹ̀ ètò láti yọ ọwọ́ ìjọba tàbí òṣèlú kúrò nínú jíjẹ oyè àti Ọba…

Ìgbìmọ̀ Ọmọ bíbí Ilẹ̀ Ìbàdàn ( Central Council of Ibadan Indigenes) ti jẹ́ kí ó di mimọ̀ pé, òun ti bẹ̀rẹ̀ ètò láti ṣe atunto eléyìí tí yóò yọ ọwọ́ kilanko ìjọba tàbí òṣèlú kúrò nínú jíjẹ oyè àti Ọba ní ìlú Ìbàdàn ní ọ̀nà láti mú iyì àti…

Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ rọ àwọn ọlọ́kadà láti gba nọ́mbà ìdánimọ̀ sí ọ̀kadà wọn

Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti sọ́ di mímọ̀ pé ètò tí nlọ láti bẹrẹ ìforúkọsílẹ àti pínpín nọmba ìdánimọ̀ fún gbogbo ẹni tí ó n fi alupupu "okada" ṣe Ajé ìgboro ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Kọmísánà fún Ètò Ìṣúná àti Ìṣirò ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Ọ̀jọ̀gbọ́n…

Gómìnà ìpínlẹ̀ Kano, Abdullahi Umar Ganduje àti ìyàwó rẹ̀ jẹ oyè ‘Ààrẹ Fìwàjoyè’ àti…

Gómìnà ìpínlẹ̀ Kano, Abdullahi Umar Ganduje ti pè fún èmí ìsọ̀kan àti ìbágbépọ̀ láàrin ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Ganduje ló sọ ọ̀rọ̀ yìí di mímọ̀ lásìkò tí Olúbàdàn Ilé Ìbàdàn, Ọba Lekan Balogun, Alli Okunmade II fi òun àti aya rẹ̀…

Mí ò ní yẹ Ìlànà ọba jíjẹ tò ti wà ní àkọsílẹ wo ni ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́.-Seyi Makinde

Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti sọ́ di mímọ̀ wípé òun ò ní ye Ìlànà àń f'obá jẹ tò ti wà ní àkọsílẹ wò nígbà tí àsìkò bá tó láti yan ẹni tí yóò jẹ Aláàfin. Gómìnà Seyi Makinde ló sọ ọ̀rọ̀ yìí di mímọ̀ lásìkò tí ìjọba ìpínlẹ̀…

Asiwaju Bola Ahmed Tinubu fi Aláàfin Ọ̀yọ́ tó wàjà, Ọba Lamidi Adeyemi III wé “ọpọ́n…

Asiwaju Bola Tinubu ló sọ ọ̀rọ̀ yí di mímọ̀ ní àsìkò tí wọ́n ṣe ádùrá ọjọ́ kẹjọ ní ìrántí ìpapòdà Aláàfin Ọ̀yọ́, Ọba Lamidi Adeyemi III. Ètò ọ̀hún ló wáyé ní Aganju tó wà ní Ààfin ìlú Ọ̀yọ́, ní ìpínlè Ọ̀yọ́ tó wà ní ẹkùn gúsù Iwọ̀ oòrùn…

Gómìná Ṣèyí Mákindé Kẹ́dùn Ikú Aláàfin Ọ̀yọ́, Ọba Làmídì Adéyẹmí III

Gómìná Mákindé, ẹni tí ó fi ìkíni ẹkú ará fẹ́rakù ránṣé sí ìgbìmọ̀ Ọ̀yọ́mèsì, ìdílée Ọba Làmídì Adéyẹmí III, àwọn ọmọ bíbí ìlú Ọ̀yọ́ àti gbogbo ọmọ Ilẹ̀ káàrọ́-ọ̀ jíire nígbàtí ó gbà ládùráà kí…

Àdánù ńlá ló sẹ lẹ̀ ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́: Ọmọọba Akeem Adeyẹmi

Ọmọọba Akeem Adéyẹmí tó s'ojú ẹkùn Ọ̀yọ́ ní Ilé ìgbìmọ̀ asòfin orílẹ̀ èdè Nàìjírìa ló so òrò yí di mímọ̀ ní Ààfin ní ìlú Ọ̀yọ́, ní ẹkùn gúsù Ìwọ òòrùn orílẹ̀ èdè Nàìjírìa nígbàtí ó sàlàyé…