Browsing Category
ÌRÒYÌN ÀṢÀ ÀTI ÌṢE YORÙBÁ
This is a category for culture and life news
Iwobi Rawọ́ Ẹ̀bẹ̀ Sí Àwọn Ọmọ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Láti Ní Sùúrù.
Ọmọ ẹgbẹ́ agbaboolu Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Alex Iwobi ti rawọ ẹ̀bẹ̀ sí àwọn olólùfẹ̀ rẹ láti ní sùúrù to pọ fún àwọn,
wọn ní àwọn yóò sa gbogbo agbara awọn láti rí wí pé àwọn kópa nínú ìdílé bọọlu àgbáyé ti ọdún 2026.
Orílẹ̀-èdè…
Ààrẹ Tinúbú Gbóríyìn Fún Ọọ̀ni Ilé Ifẹ̀ Fún Gbígbé Àṣà Àti Ìse Ilẹ̀ Yorùbá Lárugẹ
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Bọ́lá Ahmed Tinubú ti gbósùbà ràbàndẹ̀ fún Ọọ̀ni ti ilé-ifẹ̀ (Oba Adeyeye Ogunwusi) látàrí bí ó se ń gbé àṣà àti ìṣe ilẹ̀ Yorùbá lárugẹ.
Ààrẹ Tinubu wí pé, láti ìgbà Kábíyèsí ti gorí ìtẹ́ baba rẹ̀, ìṣàkóso rẹ̀…
Arólé Oòduà Ọba Adeyeye Ojaja II Ṣé Ìfilọ́lẹ̀ Ẹ̀sìn Adúláwọ̀ Ní Orílẹ̀-èdè Brazil
Ẹní ọ̀wọ̀ àtí alága àwọn Ọba lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà (National Traditional Council), Ọọ̀ni tí ilé Ifẹ, H.I.M Adeyeye Enitan Ogunwusi, Ọjaja II, tí ṣé ìfilọ́lẹ̀ ọjọ́ ẹsìn ìbílẹ̀ adúláwọ̀ tí ọdọọdún tí á pé àkọlé rẹ̀ ní "Ọjọ́ Ìṣẹ̀ṣé," ní…
Ọba Sulu-Gambari Gbóríyìn Fún Ìjọba Àpapọ̀ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Fún Ìdásílẹ̀ Ìgbìmọ̀ Aláṣẹ Ẹ̀kọ́…
Emir tí Ìlú Ilorin àti Alága Ìgbìmọ̀ Ọba àti Oyè Ìbílẹ̀ tí Ìpínlẹ̀ Kwara, Alhaji Ibrahim Sulu-Gambari tí gbóríyìn fún Ìjọba Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà fún ìdásílẹ̀ Ìgbìmọ̀ aláṣẹ ètò Ẹ̀kọ́ Ilé-ìwé gírámà tí Orílẹ̀-èdè yìí, (National Secondary…
Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Yóò Sì ilẹ́ ẹ̀kọ́ Ohun Ìṣẹ̀nbáyé.
Mínísítà fún ìròyìn, Àṣà,ati Ìṣẹ ni orílẹ̀-èdè Nàìjíríà,ń ṣiṣe lọ́wọ́lọ́wọ́ pẹ̀lú UNWTO, àwọn tọrọ kan, àti àwọn ilé iṣé aláàdáni láti rí wí pé wọ́n dá ilẹ́ ẹ̀kọ́ isẹ̀báyè sílẹ̀ ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Alhaji Lai mohammed ti o…
Ona TI Abaji,Alhaji Adamu Baba Yunusa sayẹyẹ ọdún márùndínlọ́gbọ̀n lórí ìtẹ́,ẹgbẹ́ ọmọ…
Ona of Abaji , to tun jẹ alaga igbimọ awọn lọba-lọba niluu Abuj,FCT ,His Royal Majesty (HRM) Alhaji Adamu Baba Yunusa sayẹyẹ sayẹyẹ ọdún márùndínlọ́gbọ̀n (25 years)lórí ìtẹ́, ni eyi ti gbogbo toni;e talejo wa sibi ayẹyẹ naa to waye…
Olórí Òṣìṣẹ́ Ààrẹ Gbà Oyè Ìbílẹ̀ Tintun Ní Nasarawa
Oyè ìbílẹ̀ tuntun gẹ́gẹ́bí aláàbò Ọba – “Zanna Yawu Dima ti Laffan Bare -Bari,” ní a tí fún Olórí Òṣìṣẹ́ Ààrẹ Muhammadu Buhari, Ọjọgbọn Ibrahim Gambari, ní Ààfin Emir tí Lafia, Ìpínlẹ̀ Nasarawa, Àríwá aaringbungbun Nàìjíríà.
Emir tí…
Ìpàtẹ Ọjà Àṣà Gbogbo Àgbáyé Ọdún 2022.
Ilé-iṣẹ́ Ìjọba tó mójútó ìròyìn, àṣà àti ìṣe, tí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, pèlú olùgbọ̀wọ́ àjọ àfihàn aṣa ati iṣẹ ni àgbáyé, ti bèrè ètò àfihàn aṣa àti iṣẹ ni ọjọ́ Isẹgun, ọjọ kàrún, yóò sì parí ní ọjọ́ kẹtala oṣù kẹsán ọdún 2022 ni gbọgán Amphi…
Olúbàdàn Ilẹ̀ Ìbàdàn fi àsìkò ọdún Egúngún tó ń lọ lọ́wọ́ ní ìlú Ìbàdàn gbàdúrà fún àlàáfíà àti…
Olúbàdàn Ilẹ̀ Ìbàdàn, Ọba Olalekan Balogun, Alli Okunmade II ti fi àsìkò ọdún Egúngún tó tí bẹ̀rẹ̀ ní igun mẹrẹrin ìlú Ìbàdàn gbàdúrà fún àlàáfíà àti ìṣọ̀kan orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Ọdún Egúngún eléyìí tó má n wáyé lọdọọdun…
Olúbàdàn ilẹ̀ Ìbàdàn kìlọ̀ fún àwọn eégún ṣáájú ọdún Egúngún tó ń bọ̀.
Olúbàdàn ilẹ̀ Ìbàdàn, Ọba Olalekan Balogun, Alli-Okunmade II ti tẹ̀ẹ́ mọ́ gbogbo àwọn tí yóò kópa nínú ọdún Egúngún tí ọdún yìí, eléyìí tí yóò bèrè ní ọjọ́ Ajé (27/06/2022) láti yàgò fún ìwà ipanle eléyìí tó sábà máa ń wáyé.
Ọba…