Ẹgbẹ́ Oníròyìn Nàìjíríà Pẹ̀lú Àwọn Àkẹgbẹ́ Wọ́n Látí Orílẹ̀-èdè America Ṣé Ìdánilẹ́kọ̀ọ́ Fún Àwọn…
Ẹgbẹ́ àwọn òníròyìn Nàìjíríà (NUJ), Ìgbìmọ̀ Ìpínlẹ̀ Èkó lábẹ́ Alága wọ́n Ọ̀gbẹ́ni Adeleye Ajayi, tí ṣé ọ̀pọ̀lọpọ̀ akitiyan ní àgbègbè ikẹkọ fún àwọn ọmọ ẹgbẹ́.
Gẹ́gẹ́ bí èròngbà ẹgbẹ́ náà láti rí dájú pé àwọn òníròyìn ìpínlẹ̀ Èkó ìmọ…