Take a fresh look at your lifestyle.

Àwọn Aṣojú Ìjọba Ilẹ̀ Áfíríkà Kẹ́dùn Olóògbé Nujoma Pẹ̀lú Nàmíbíà

Ìgbìmọ̀ Àwọn aṣojú orílẹ̀-èdè Áfíríkà tí darapọ̀ mọ́ àwọn yòókù lágbayé láti ṣọfọ ikú Sam Nujoma, Ààrẹ àkọkọ́ ní Orílẹ̀-èdè Namibia lẹyìn òmìnira, tó kú ní ẹní odún márún dín lọgọ́rùn (95). ‎ ‎ Nujoma jẹ́ olókìkí ajá-fẹtọ́-ọmọnìyàn,…

FUHSI VC Rọ́ Àwọn Ọmọ Ilé-ìwé Rẹ̀ Látí F’akọyọ Lórí Ètò Ẹ̀kọ́ Wọ́n Pẹ̀lú Ìwà Réré

‎ Ìgbákejì Adarí (VC) tí Ilé-ìwé gíga 'Federal University of Health Sciences, Ila-Orangun (FUHSI)', Ìpínlẹ̀ Osun, Ọ̀jọ̀gbọ́n Akeem Lasisi tí rọ́ àwọn ọmọ ilé-ìwé rẹ̀ túntún látí kọ́ ẹ̀kọ́ àti ìhùwàsí tó dára. ‎ ‎ Ọ̀jọ̀gbọ́n Lasisi sọ pé…

Orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà Fún Nàìjíríà Ní Ẹgbẹ̀rún Lọnà Àádọ́run Dọla ‎

Ìjọba Orílẹ̀-èdè Améríkà ló fún Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ní owó ẹbùn ẹgbẹ̀rún lọnà àádọ́run dọla ($90,000) latari àdéhùn àjọṣepọ̀ lórí ìtọ́jú Oun-ìní Àṣà tí ìnáwó Ọdún 2023, fún ìdáàbòbò àwọn òun-ìní àti òun ọ̀ṣọ́ Nok. ‎ ‎ Ẹbùn owó náà ní…
button