Take a fresh look at your lifestyle.
Election

Ẹgbẹ́ Oníròyìn Nàìjíríà Pẹ̀lú Àwọn Àkẹgbẹ́ Wọ́n Látí Orílẹ̀-èdè America Ṣé Ìdánilẹ́kọ̀ọ́ Fún Àwọn…

Ẹgbẹ́ àwọn òníròyìn Nàìjíríà (NUJ), Ìgbìmọ̀ Ìpínlẹ̀ Èkó lábẹ́ Alága wọ́n Ọ̀gbẹ́ni Adeleye Ajayi, tí ṣé ọ̀pọ̀lọpọ̀ akitiyan ní àgbègbè ikẹkọ fún àwọn ọmọ ẹgbẹ́. Gẹ́gẹ́ bí èròngbà ẹgbẹ́ náà láti rí dájú pé àwọn òníròyìn ìpínlẹ̀ Èkó ìmọ…

Ètò Ìdìbò Ilé-ìgbìmọ̀ Aṣòfin Ìpínlẹ̀, Gómìnà Ìpínlẹ̀ Osun Kéde Ìsìnmi Lẹ́nù-iṣẹ́ Ọjọ́ Ẹtì

Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun, Sẹnetọ Ademọla Adeleke tí kéde ìsinmi lọjọ́ Ẹtì ṣáájú ètò ìdìbò ilé-ìgbìmọ̀ aṣòfin ìpínlẹ̀ náà tí yóò wáyé ní ọjọ́ Ẹtì. Èyí wà nínú àtẹ̀jáde tí agbẹnusọ Gómìnà, Mallam Olawale Rasheed sọ́ fún òníròyìn VON ní Osogbo…

Ààrẹ Buhari Kóró-ojú Sí Ìkọlù Túntún Tí Àwọn Ẹ́ṣìn-ó-kọ́ku Ṣé Ní Ìpínlẹ̀ Kaduna

Ààrẹ Muhammadu Buhari sọ́ wípé iyalẹnu ló jẹ́ fún òún látí gbọ́ pé àwọn ẹsìn-ó-kọ́ku tún ṣé ikọlù ìpànìyàn sí ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ẹ̀mí aláìṣẹ ní ìjọba ìbílẹ̀ Zangon Kataf ní ìpínlẹ̀ Kaduna. Ààrẹ Buhari sọ pé kí àwọn òṣìṣẹ́ Ilé-iṣẹ́ Ààbò…

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Osun Ṣé Ìdánilójú Ìgbéga Ilé-ìwé Gíga Iléṣà

Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun, Sẹnetọ Ademọla Adeleke sọ pé Yunifásítì túntún Iléṣà tí fí ìdí múlẹ̀ àtí pé iṣẹ́ àtúnṣe rẹ̀ tí bẹ̀rẹ̀ báyìí. Gómìnà ṣàlàyé èyí ní ọjọ́ Ẹtì ní Iléṣà làkókò àbẹwò lẹ́nú iṣẹ́ sí ilé-ẹ̀kọ́ náà látí ṣàyẹ̀wò àwọn òun èlò…

ìdánilẹ́kọ̀ọ́ Ìkẹ́kọ̀ Bẹ̀rẹ̀ Fún Àwọn Olùkọ́ní Ní Ìpínlẹ̀ Ebonyi

Àjọ tó ń pèsè iṣẹ́ ní orílẹ̀-èdè yìí (National Directorate of Employment NDE) ní Ìpínlẹ̀ Ebonyi ní Gúúsù ìlà oòrùn Nàìjíríà tí bẹ̀rẹ̀ ikẹkọ àgbàrá fún àwọn olùkọ́ní rẹ̀. ìdánilẹ́kọ̀ọ́ náà wáyé látí fí awọn òun èlò ìgbàlódé kọ́ àwọn…