Browsing Category
ÌRÒYÌN ÀṢÀ ÀTI ÌṢE YORÙBÁ
This is a category for culture and life news
Ayẹyẹ Ọjọ́ Ìjọba Tiwantiwa Parí Pẹ̀lú Àrà Àti Ẹ̀yẹ Ní Ìlú Abuja
Àwọn ètò pàtàkì tí a là sílẹ̀ fún ayẹyẹ ọjọ́ ìjọba tiwantiwa ti ọdún yìí ti parí pẹ̀lú àrà àti ẹ̀yẹ ní orí pápá Eagle Square, ní ìlú Abuja.
Aarẹ Muhammadu Buhari, ẹni to jẹ alejo pataki nibi ayẹyẹ náà wa ni…
Olúbàdàn ilé Ìbàdàn, gba àwọn olóyè tó gba ìgbéga níyànjú.
Olúbàdàn ilé Ìbàdàn, Ọba Lekan Balogun gba àwọn olóyè àgbà tó ṣẹ̀ gba ìgbéga níyànjú.Olúbàdàn ilé Ìbàdàn, Ọba Lekan Balogun, Alli Okunmade II ti gba àwọn olóyè àgbà márùn tí wọ́n gba ìgbéga láti ìpele kan sí òmíràn níyànjú láti rí ara wọn…
Mí ò ní yẹ Ìlànà ọba jíjẹ tò ti wà ní àkọsílẹ wo ni ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́.-Seyi Makinde
Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti sọ́ di mímọ̀ wípé òun ò ní ye Ìlànà àń f'obá jẹ tò ti wà ní àkọsílẹ wò nígbà tí àsìkò bá tó láti yan ẹni tí yóò jẹ Aláàfin.
Gómìnà Seyi Makinde ló sọ ọ̀rọ̀ yìí di mímọ̀ lásìkò tí ìjọba ìpínlẹ̀…
Asiwaju Bola Ahmed Tinubu fi Aláàfin Ọ̀yọ́ tó wàjà, Ọba Lamidi Adeyemi III wé “ọpọ́n…
Asiwaju Bola Tinubu ló sọ ọ̀rọ̀ yí di mímọ̀ ní àsìkò tí wọ́n ṣe ádùrá ọjọ́ kẹjọ ní ìrántí ìpapòdà Aláàfin Ọ̀yọ́, Ọba Lamidi Adeyemi III. Ètò ọ̀hún ló wáyé ní Aganju tó wà ní Ààfin ìlú Ọ̀yọ́, ní ìpínlè Ọ̀yọ́ tó wà ní ẹkùn gúsù Iwọ̀ oòrùn…
Gómìná Ṣèyí Mákindé Kẹ́dùn Ikú Aláàfin Ọ̀yọ́, Ọba Làmídì Adéyẹmí III
Gómìná Mákindé, ẹni tí ó fi ìkíni ẹkú ará fẹ́rakù ránṣé sí ìgbìmọ̀ Ọ̀yọ́mèsì, ìdílée Ọba Làmídì Adéyẹmí III, àwọn ọmọ bíbí ìlú Ọ̀yọ́ àti gbogbo ọmọ Ilẹ̀ káàrọ́-ọ̀ jíire nígbàtí ó gbà ládùráà kí…
Àdánù ńlá ló sẹ lẹ̀ ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́: Ọmọọba Akeem Adeyẹmi
Ọmọọba Akeem Adéyẹmí tó s'ojú ẹkùn Ọ̀yọ́ ní Ilé ìgbìmọ̀ asòfin orílẹ̀ èdè Nàìjírìa ló so òrò yí di mímọ̀ ní Ààfin ní ìlú Ọ̀yọ́, ní ẹkùn gúsù Ìwọ òòrùn orílẹ̀ èdè Nàìjírìa nígbàtí ó sàlàyé…
IGI ǸLÁ WO, ALÁÀFIN Ọ̀YỌ́,ỌBA LAMIDI ADEYẸMI PAPÒDÀ
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo sọ pe Alaafin ti ilu Oyo, Oba Lamidi Adeyemi ti jáde láyé.
Ẹni ọdun mẹtalelọgrin ni Alaafin nigba to jade laye, oun si ni Alaafin to ti jọba fun odidi ọdún mejilelaadọta.
Ẹ̀kúnrẹ́rẹ́…
Ẹ jáwọ́ nínú dídábẹ́ fún àwọn ọmọbìnrin-Oluwakemi Olawoyin
Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ pẹ̀lú àjọsepọ̀ ajọ Hacey Health Initiative ló se àgbékalẹ̀ ìdánilẹ̀ẹ̀kọ́ fún awọn akọroyin ni ipinlẹ Ọ̀yọ́ lori ipa ti wọn le ko lati fi opin si ìdábẹ́ fun awọn ọmọbinrin (Female Genital Mutilation, FGM)…
Emir Kaiama fi Ahmad Lawan, AbdulRahman AbdulRazaq jẹ oyè Magayaki ,Kaura Kaiama
Adari ile igbimọ asofin agba, Ahmad Lawan ati gomina ipinlẹ Kwara ,AbdulRahman AbdulRazaq ni Emir ti illu Kaiama ti fi jẹ oye Magayaki ati Kaura Kaiama lọjọ Aiku yii..
Emir ti ilu Kaiama ,Alhaji Muazu Shehu Omar ni isẹ ribi-ribi ti…
Olalekan Ishọla Balogun di Olúbàdàn kejìlélógójì
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde ti fi idunnu rẹ han si olubadan tuntun, Ọba Olalekan Ishọla Balogun, Alli Okumade 2, ẹni ti o gba ọ̀pá àsẹ gẹgẹ bi Olubadan kejilelogoji lẹyin ọjọ́ Mejilelaadọrin ti olubadan ana, Oba Saliu Adetunji…