Dangote Foundation Fi Ọgọ́rùn ún Ẹgbẹ̀rún Àpò Ìrẹsì Ṣe Ìtọrẹ Ní Ìpínlẹ̀ Kano
Ni ákokó aawe ati ẹ̀mí oṣù Ramadan mímọ́, Dangote Foundation ti fi Ogorun Egberun Àpò Irẹsi ṣe ìtọrẹ fún àwọn olùgbé to ku díẹ kaato fun ní gbogbo Ìpínlẹ̀ Kano ní Àríwá Ìwọ̀ Oòrùn Nàìjíríà.
Akọ̀wé fún Ìjọ́ba Ìpínlẹ̀, Alhaji Umar Farouk…