Take a fresh look at your lifestyle.

Àwọn Ọmọ Ilé-igbimọ Aṣofin Kano mẹjọ ti pada Sínú Ẹgbẹ́ Òṣèlú APC Láti Inú Ẹgbẹ́ Òṣèlú NNPP

Gómìnà ìpínlẹ̀ Kano, Abba Yusuf, ti rí ìyípadà ńláǹlà nínú oṣèlú ní ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà ní Abuja nígbà tí àwọn mẹ́jọ nínú ilé ìgbìmọ̀ aṣojú sòfin láti ìpínlẹ̀ Kano ti fi ẹgbẹ́ òṣèlú New Nigeria Peoples Party (NNPP) padà sínu ẹgbẹ…

Ilé-igbimọ Aṣòfin Nàìjíríà Ti Gba Ètò Ìṣúná Tó Dín Díẹ̀ Ní Àádọ́rin Tíríníọ̀nù Náírà, N68.3Trn Ti…

Ilé-igbimọ aṣofin Naijiria ti gba Isuna ọdun 2026 wọlé lẹhin ti o ti fi owo tó lè diẹ ni Tirilonù,N9.3 mẹsan Naira kun, bi Aare Bola Tinubu ti béèrè fún bí àfikún, ti o mu iye naa wa si owó to din diẹ ni Àádọ́rin Tirinionu Náírà, N68.3Trn.…

Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Fọwọ́ Sí Ẹ̀bùn Fífúnni Fún Ètò Ìwádìí

Ìjọba Àpapọ̀ ti fọwọ́ sí ìdásílẹ̀ Ètò ẹ̀bùn olodọodún, "Nigeria National Laureate Annual Prize Programme", ètò pàtàkì kan tí a ṣe láti dá àwọn ìwádìí ẹ̀kọ́ tó tayọ, ìtayọ ọpọlọ, àti àwọn ìṣẹ̀dá tuntun tó ṣeé ṣe ní ti ìṣòwò mọ̀ láti ọ̀dọ̀…

Ìjọba Nàìjíríà Tún Fi Ìdí Rẹ̀ Múlẹ̀ Láti Ró Àwọn Ilé-iṣẹ́ ìÌera Tó Wà Ní Ipò Gíga Lágbára Síi

Ìjọba Nàìjíríà ti tún fi ìdúróṣinṣin rẹ̀ múlẹ̀ láti fún àwọn ilé ìlera gíga lágbára gẹ́gẹ́ bí ìpìlẹ̀ fún ìdàgbàsókè orílẹ̀-èdè yìí àti àbájáde ìlera gbogbogbòò kí ó dára síi. Minisita fún Ìlera àti Àlàáfíà Àwùjọ, Ọ̀jọ̀gbọ́n Ali…
button