Browsing Category
ÌRÒYÌN ÈTÒ Ọ̀GÌN ÀTI ÀYÍKÁ
Omi: Ọ̀nà Kan Gbógì Láti Ní Àlàáfíà Tó Péye Ni Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Ilé iṣé àdáni tí o n jẹ clean- up Nigeria (CUN) sọ wí pé ọnà kan gbógì láti ní ìbáṣepọ̀ tó dán móran àti àlàáfíà ni ki wọn ni omi tó péye.
Ọgbẹni Ebè Ọwọh to je alàkóso fún ẹgbẹ́ CUN lo sọ èyí di mímọ nígbà tí o n ba àwọn oníròyìn sọ̀rọ̀…
Ó Tó Ẹgbẹ̀rún Mẹ́ta Àpò Ògùn Olóró Ti Àjọ NDLEA Dá Iná Sun Ni Ìpínlẹ̀ Edo.
Ó kéré ó tó ẹgbẹrun mẹta àpò ògùn olóró tí àjọ NDLEA Dá iná sun, ni inu oko, tí o wa ni igueben ni ìpínlẹ̀ Edo.
Ọgbẹni Fẹmi Babafemi tó jẹ́ agbenuso fún Àjọ náà ló sọ èyí di mímọ ní ọjọ́ ìsinmi ni ìlú Abuja.
Babafemi ni àwọn afurasi…
Àwọn Àgbẹ̀ Olóhun Ọ̀sìn Pè Fún Ìtèsíwájú Nípa Fífún Àwọn Ọmọ Ilé Ìwé Ní Oúnjẹ.
Àwọn àgbẹ̀ ọlọhun ọ̀sìn ni ìpínlẹ̀ Ẹkọ tí pé fún ìtèsíwájú fífún àwọn ọmọ ilé ìwé ni oúnjẹ láti mú ìdàgbàsókè àti ìlọsíwájú bá ètò ẹkọ àti àwọn àgbẹ̀
Nínú ibanisọrọ pẹlú àwọn àgbẹ̀ ọlọhun ọ̀sìn ni ọrọ náà ti jáde.
Ètò fifun àwọn ọmọ…
Mímú Ìgbòòrò Bá Ètò Ọ̀gbìn Yóò Sàlékún Ètò Ààbò, Ìléṣẹ̀ẹ́wọ̀gbẹ́
Ọ̀gbẹ́ni Peter Obi, tí ó jẹ́ olùdíje sí ipò ààrẹ lábẹ́ àsìá ẹgbẹ́ òsèlú LP nínú ìdìbò gbogbogbòò tí ó kọjá sọ pé, mímú ìgbòòrò bá ètò ọ̀gbìn yóò tán ìsòro àìrajaja ètò àbò, òsì, ọ̀wọ́gógó…
Àjọ NEMA Se Ìdánilẹ́kọ̀ọ́ Fún Àwọn Onísòwò Lórí Pàtàkì Ìdènà Ewu
Àjọ NEMA ti se ìdánilẹ́kọ̀ọ́ fún àwọn onísòwò ọjà Census, Surulere, Ìlú Èkó, lórí pàtàkì ìdènà ewu fún ìdáàbòbò dúkìá àti ẹ̀mí ọmọnìyàn
Àwọn àgùnbánirọ̀ ẹka NEMA ni ó se agbátẹrù ètò náà…
Ìjọba Àpapọ̀ Ń gbé Ìgbésẹ̀ Láti Yá Bílíọ̀nù Kan Dọ́là Lójúnà Àti Mú Ìgbòòrò Bá…
Ìjọba àpapọ̀ ti ń se ìgbésẹ̀ láti yá owó tí ó tó bílíọ̀nù kan dọ́là láti ọwọ́ báńkì àgbáyé lójúnà àti tán ìsòro tí ó ń kojú àwọn tí ìdágìrì lé kúrò ní ibùgbé wọn àti láti mú ìgbòòrò bá…
Ìmọ́tótó Ọlọ́ṣẹ̀-ọ̀ṣẹ̀ Gbérasọ Ní Àwọn Ọjà Gbogbo Ní Ìpínlẹ̀ Ekiti
Ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti ti kéde bíbẹ̀rẹ̀ Ètò ìmọ́tótó ọlọ́ṣẹ̀-ọ̀ṣẹ̀, èyí tí yóò máa wáyé ní Ọjọ́bọ̀ ní àwọn ọjà gbogbo ní ìpílẹ̀ Èkìtì
Kọmísọ́nà Fún Ọ̀rọ̀ Àgbègbè Àti Ohun Àlùmọ́ọ́nì ní ìpínlẹ̀…
Ìrọ̀rùn Dé, Ọ̀wọ́ngógó Oúnjẹ Yóò Dẹ̀rọ̀: Àwọn Alẹ́nulọ́rọ̀ Fọwọ́sowọ́pọ̀ Pẹ̀lú Ìjọba…
Lójúnà àti mú kí oúnjẹ pọ̀ yanturu ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, àwọn ilé iṣẹ́ kan ti dìde ìrànlọ́wọ́ fún ìjọba àpapọ̀ láti jẹ́ kí ìlérí náà wá sí ìmúsẹ nígbà tí wọ́n jẹ́jẹ̀ẹ́ láti se ìrànlọ́wọ́ fún àwọn…
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kebbi San Owó Fún Àwọn Ti Yòó Ṣe Àtúnṣe Àwọn Pópónà Ìgbèríko.
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kebbi ti san Mílíọ̀nù Mẹta ole ni àádọta Náírà fún àwọn òṣìṣẹ́ (RAAMP) ti yóò ṣe àwọn pópónà ìgbèríko.
Alhaji Shehu Mu'azu tó jẹ Kọmísọ́nà fún ètò ògbìn àti iṣé ìgbèríko lo sọ èyí di mímọ ní ọjọ́ ajé ni kebbi nígbàtí o n…
Ìmọ̀ Nípa Ìyípadà Ojú Ọjọ́ Se Pàtàkì Fún Àwọn Akẹ́kọ̀ọ́- Alẹ́nulọ́rọ̀ Kan kégbàjarè
Mallam Nurudden Bello tí ó jẹ́ alákòsóo ilé ẹ̀kọ́ ìmọ̀ ètò ìlera ní ìpínlẹ̀ Kaduna ti sàlàyé pàtàkì ìmọ̀ nípa ìyípadà ojú ọjọ́ fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ lójúnà àti tán ìsòro tí ìsẹ̀lẹ̀ náà ń mú bá àwùjọ…