Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌDÁNILÁRAYÁ
This is a category for entertainment news
Akọrin Ìgbàgbọ́ Ọmọ Amẹ́ríkà Papòdà Ní Ẹni Ọ̀kànlélọ́gọ̀rin Ọdún
Gbajúmọ̀ akọrin ìgbàgbọ́ ọmọ ilẹ̀ Amẹ́ríkà, adari ìyìn àti olùṣọ àgùntàn, Ron Kenoly ti papòdà ní ẹni Ọ̀kànlélọ́gọ̀rin Ọdún.
Iku rè ní wọn sọ pé o wáyé ní ojó keta oṣù keji ọdún 2026, ti gbogbo ènìyàn paapaa julọ láti ìdílè…
Àjọ FIFA Ṣe Atilẹyin láti Gbeẹ́Òfin kúrò Lórí Orílè-èdè Russia: Ààrẹ FIFA Infanitino
Ààrẹ FIFA, Gianni Infantino, sọ wí pè oun ṣe àtìlẹ́yìn lati gbe ofin kúrò lori Russia ni ọdun mẹrin lati ko pa nínú awọn ere-idije kariaye nitori pe ko ṣe aṣeyọri nkankan”.
Awọn ẹgbẹ Russia ati ẹgbẹ orilẹ-ede ti daduro fun awọn idije…
Òṣèré Tíátà Abubakar Yakubu Bẹ̀rẹ̀ Isẹ́ Gẹ́gẹ́ Bíi Ọgá Tuntun Fún Ẹgbẹ́ AGN.
Ẹgbẹ́ òṣèré ti wọn n pé ni Actor Guild Of Nigeria AGN ti ki Ààrẹ tuntun káàbò sí ẹnu iṣẹ Abubakar Yakubu ni ìlu Abuja.
Ìròyìn fi yè wa wí pè Ààrẹ tuntun náà búra láti bẹ̀rẹ̀ isẹ́ ni ilè iṣẹ́ AGN ni ìlu Abuja.
Yakubu ló bo sí ipò lẹyìn…
Gómìnà Zulum Gbàlejò Ìpàdé Àsà Ti Kanem-Borno
Gomina ipínlẹ̀ Borno, Babagana Umara Zulum, ti gbàlejò ìpàdé ọ̀gọ̀rọ̀ ẹgbẹgbẹ̀run ẹ̀yà ènìyàn Kanuri ó kéré tán orílẹ-èdè mẹ́wàá láti Ilẹ̀ Adúláwọ̀ tó wá síbi ìpàde àṣà ti Kanem-Borno tó wáyé ní ìlú Maiduguri.
Ìpàdé náà ṣe àgbájọpọ̀ Emir…
Ọ̀jọ̀gbọ́n Soyinka Polongo Gbígbé Èdè Àbínibí Ilẹ̀ Wa Lárugẹ
Ọ̀jọ̀gbọ́n Wole Soyinka-"Nobel Laureate", ti tẹnumọ bó ṣe se pàtàkì láti gbé èdè abínibí ilẹ̀ wá àti àṣà òjogúnbá lárugẹ, wípé ó jẹ́ ohun ìwúlò pàtàkì fún ìdàgbàsókè orílẹ̀-èdè .
Ó sọ èyí ní ọjọ́ Ajé níbi ti o ti ń dáhùn ìbéèrè láti ọdọ…
Mínísítà Ọ̀rọ̀ Nípa Àwọn Obìnrin Kí Ọpẹ́yẹmí Bright Kú Oríire Oyè Mayor.
Mínísítà tó ń ri sì ọ̀rọ̀ nípa àwọn Obìnrin, Hajiya Imaan Sulaiman-Ibrahim ti kí Princess Opeyemi Bright ku oríire bí o ti fìtàn balẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọ̀dọ́mọdebìnrin tó kéré jùlọ Mayor ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì.
Bí ètò ifinijoye rẹ yóò ṣe waye ni…
Burna Boy Yóò Se Eré Ọ̀fẹ́ Fún Àwọn Ololufẹ Rẹ̀ Ní Orílè-èdè Burkina Faso
Ìràwọ akọrin ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà sọ èyí di mímọ̀ lórí ẹ̀rọ ayélujára Instagramu rẹ̀ ni ọjọ́ kẹtàdínlogun oṣù kàrún ọdún 2025 pé òun ṣe eré ní orílẹ̀-èdè Burkina Faso.
"Ti o bá seése, fún mi, iyì ni yóò jẹ fún mi láti seré ọ̀fẹ́…
Akọrin Ọmọ Orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà Kan Kú Sínú Ìjàmbá Iná Inú-ilé
Jill Sobule, gbajúmọ̀ akọrin, olùkọrin-sílẹ̀ Ọmọ Orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà ti wọ́n mọ̀ nípa àkọlé orin rẹ̀ - "LGBTQ+ hit “I Kissed a Girl,” ti ku sínú Ìjàmbá iná inú-ilé ní Woodbury, Minnesota.
Akéde orin ló fi ìròyìn ikú rẹ̀ léde…
Gbajúmọ̀ Òsèrébìrin Kéde Ìpadàbọ̀ Sí Agbo Òṣèlú
Gbajúmọ̀ òsèrébìrin àti olùṣe fíìmù, Funke Akindele ti kéde èròngbà rẹ láti padà sí agbo òṣèlú látàrí ìfẹ́ tó ní láti sìn ìlú.
Akindele tó jẹ́ igbákejì Olùdíje sí ipò Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkó lábẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP nínú ìbò gbogbogbòò ọdún 2023…
Davido Gba Àmì Ẹ̀yẹ Headies award Ẹlẹ́ẹkẹtàdínlógún Akọrin Òrí Ayélujára Tó Dára Jùlọ
Gbajúmọ̀ Ìràwọ akọrin tàkasùfé ọmọ orílẹ̀-èdè yìí, David Adeleke, tó ti gbá ọpọ àmì ẹ̀yẹ ti gbogbo ènìyàn mọ̀ sì Davido ti gba àmì ẹ̀yẹ Headies award Ẹlẹẹkẹtadinlogun akọrin orí Ayelujara to dára jùlọ ti ọdún yìí.
Àwo rẹ bii “Ogechi Remix”…