Take a fresh look at your lifestyle.
Election

Àwọn Oníṣègùn Òyìnbó Orílẹ̀-èdè British Bẹ̀rẹ̀ Ìyansẹ́lódì Ọlọ́jọ́ Mẹ́ta.

Ẹgbẹrun àwọn Oníṣègùn Òyìnbó ló bẹ̀rẹ̀ ìyansẹ́lódí látàrí owó oṣù tí kò ṣe dédé. Ẹgbẹ́ àwọn Oníṣègùn Òyìnbó sọ pé owó sísan fún àwọn Oníṣègùn kékèké ko gbọdọ kéré sí 14.09 pound fun wákàtí kan, wọ́n ní tó ba tí kéré sí èyí àbùkù ni.…

Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Dárò ikú Sẹ́nítọ̀ Obìnrin Àkọ́kọ́.

Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Muhammad Buhari ti ba ẹbí àti ara kẹ́dùn ikú Sẹ́nítọ̀ Obìnrin àkọ́kọ́ ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà France Afegbua èyí tí iṣé rẹ jẹ ìwúrí fún àwọn obìnrin. Lábẹ àsìá ẹgbẹ́ òṣèlú National Party Of Nigerian (NPN). Ààrẹ…

Ọ̀gágun Àwọn Ológun Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Rọ Àwọn Ọmọ Ológun Láti Riwọ́ Àwọn Agbésùmọ̀mí Bọlẹ̀.

Ọ̀gágun àgbà àti aláṣẹ fún ẹkùn keje fún HADIN KAI ọgagun Waidi Shuiabu ti rọ àwọn ọmọ ogun Force Brigade lati gbaradì ni gbogbo igba ki wọn le koju awọn oniṣẹ láabi Boko Haram ati alatako ẹ̀sìn Musulumi. Ọ̀gágun Shuiabu sọ èyí ni…

Aláàkóso Àjọ NYSC ṣe ìkìlọ̀ fún àwọn ará ìlú láti jáwọ́ wíwọ aṣọ àgùnbánirò lọ́nà…

Alákoso fun àjọ ẹgbẹ́ àgùnbánirọ̀ lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí ṣe ìkìlọ pàtàkì lórí ẹwu to wa ninu wiwọ aṣọ, lilo ààmì, orin àti àwọn èlò àgùnbánirọ̀ Lai gbà àṣẹ. Ọ̀rọ̀ yìí jáde láti ọwó Olùdarí àti alukoro fún àjọ àgùnbánirọ̀,…

IWD 2023: Gómìnà ìpínlẹ̀ Anambra Gbósùbà Fún Àwọn Obìnrin A Mú Ìlú Dàgbà Sókè.

Gómìnà ìpínlẹ̀ Anambra ọ̀mọ̀wé Chukwuma charles Soludo ti sọ ipa ti àwọn obìnrin n kò nípa Ìdàgbàsókè Ìlú gẹ́gẹ́ bí ohun tí kò ṣe fọwọ́ rọ sẹ́yìn. Gómìnà Soludo sọ èyí nínú àtẹjáde láti ọwọ́ Akọ̀wé rẹ, ni ọjọ́ ayẹyẹ àyájọ́ awọn obìnrin…