Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌLERA
This is a category for health news
Àti Ni Àwon Ìpinu Àti ọnà Abayọ Sí Omi Tó Mọ Tonitoni: Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ẹkọ.
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Eko tí sí Aso lójú egún, Látàrí wí pé wọn sọ fún àwọn ènìyàn lórí ìpinu wọn lórí Omi Tó Mọ Tonitoni.
Wọn ni èyí wà ní ìbámu pẹlú atilẹyin ati akitiyan àjọ àgbáyé UN.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Eko, Gómìnà Sanwó -Olu sọ wí pé ìpinu…
Èròngbà Wa Ni Ki Àjọ NCDC Di Gbájugbàja kàkàkíri Àgbáyé: Adarí Àgbà Pátápátá
Adari àgbà pátápátá fún àjọ NCDC, Dọ́kítà Jide Idris ti sàlàyé èròngbà rẹ láti rí wí pé Àjọ NCDC di ìlú mọ ká lágbayé.
Ó sọ èyí di mímọ nígbà tí ó ń ba àwọn oníròyìn sọ̀rọ̀ ní ọjọ́ ìsinmi ni ìlú Abuja, nibe ní ó ti ń sàlàyé nípa àwọn…
Ẹ Sàmójútó Àlàáfíà Ara Yín Lásìkò Iṣẹ́- Alága Ẹgbẹ́ Oníwòsàn Eyiń Pàrọwà
Alága Àpapọ̀ Ẹgbẹ́ Oníwòsàn Eyín, Dọ́kítà Tọpẹ Adeyẹmi ti sàlàyé ìdí tí ó fi yẹ kí àwọn dókítà sàmójútó àlàáfíà ara wọn b́i wọ́n se ń tọ́jú àwọn aláìsàn
Ó tẹ̀síwájú pé, bí ó se se pàtàkì…
Ilé Iṣẹ́ Kan Nawọ́ Àánú Sí Ibùdó Ìsàtúnṣe Ọmọ Òrukàn Ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Ó Pèsè Iná…
Ilé Isẹ́ kan ti pèsè iná mọ̀nà-mọ́ná èyí tí ó ń lo agbára òòrùn fún ilé ìsàtúnse ọmọ òrukàn tí a mọ̀ sí (Jesus Children Mossion Outreach) ní ìlú Ibadan láti se ìrànlọ́wọ́ fún àwùjọ
Asojú Ilé…
Ẹgbẹ̀rún Méjìlélọ́gbọ̀n Ènìyàn Lùgbàdì Àìsàn Ikọ́ Féére Ní Ìpínlẹ̀ Kaduna, Ní…
Kọmísọ́nà Fún Ètò Ìlera ní Ìpínlẹ̀ Kaduna, Hajiya Umma Kaltume Ahmed ti sàlàyé pé ó lé ní ẹgbẹ̀rún méjìlélọ́gbọ̀n ènìyàn tí ó lùgbàdì àìsàn ikọ́ féére ní ọdún 2023
Ó síṣọ lójú ọ̀rọ̀ náà níbi…
Sẹ́nétọ̀ Olurẹmi Tinubu Pè Fún Fífi Òpin Sí Àìsàn Ikọ́ Féére
Aya Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Sẹ́nétọ̀ Olurẹmi Tinubu ti pè fún ojúse tí ó yanjú láti rí i dájú pé àìsàn ikọ́ féére di àfìsẹ́yìn tí egúngún ń fi aṣọ láwùjọ àti ní pàtàkì jùlọ ní gbogbo àwọn…
Àjọ NNPC, TOTAL, Fi Ilé Ìwòsàn Ta Ìletò Kan Lọ́rẹ Ní Ìpínlẹ̀ Kaduna
Àjọ Elépo Rọ̀bì NNPC, TOTAL, ti kọ́ ilé ìwòsàn kan láti fi se ìtọrẹ àánú fún ìletò Kwoi, ìjọba ìbílẹ̀ Jaba, ìpínlẹ̀ kaduna fún ìtọ́jú àwọn aláboyún àti àwọn ọmọdé ní àgbègbè náà
Nígbà tí ó ń…
Àwọn Ènìyàn Tó Tó Ẹgbẹrun Mẹ́fà Lo Jẹ Anfààní Ètò Ìtọjú Ìlera Ọ̀fẹ́ Ni Ìpínlẹ̀ Imo.
Ó kéré jù àwọn ẹgbẹrun mẹ́fà ènìyàn ní yóò jẹ anfààní ètò ìtọjú ìlera Ọ̀fẹ́ ni ìpínlẹ̀ Imo èyí tí Mbana National Assembly gbé kalẹ. Wọn ni yóò tó ọgọrùn mílíọ̀nù méjì náírà ni wọn gbé kalẹ fún ètò náà.
Ìtọjú Ọ̀fẹ́ náà wáyé ní ilé ìwòsàn…
Mílíọ̀nù Méjìàbò Ènìyàn Ilẹ̀ Adúláwọ̀ Lùgbàdì Àìsàn Ikọ́ Féére Ní Ọdún 2022-…
Àjọ WHO ti sàlàyé pé, ó lé ní mílíọ̀nù méjì-àbọ̀ tí ó lùgbàdì àìsàn ikọ́ féére ní ilẹ̀ Adúláwọ̀, ní ọdún 2022
Alákòóso àjọ náà fún ilẹ̀ adúláwọ̀, Dokita Matshidiso Moeti sọ ọrọ naa ni ayajọ…
Aya Gómìnà Ìpínlẹ̀ Anambra Sèkìlọ̀ Láti Jìnà Sí Ìgbé Ayé Tí Ó Léwu Fún…
Olùdásílẹ̀ àjọ aláàánú kan tí kì í se ti ìjọba, Arábìnrin Nonye Soludo ti sèkìlọ̀ láti jìnà sí ìgbé ayé tí ó le è sàkóbá fún ìlera ara, àtipé àlàáfíà tí ó péye máa ń wáyé láti ara àmójútó,…