Browsing Category
ÌRÒYÌN ORÍLẸ̀-ÈDÈ NÀÍJIRÍÀ
This is a Nigeria news category
Àdínkù owó epo ilẹ̀: Ìjọba Nàìjíríà ṣèpàdé pẹ̀lú ìgbìmọ̀ ẹgbẹ́ kátàkár̀a
Ìjọba Nàìjíríà n ṣepade pẹ̀lú àwọn aṣojú ìgbìmọ̀ ẹgbẹ́ kátàkár̀a (TUC), lọ́wọ́ báyìí, ní gbọ̀ngàn ààrẹ, ní Villa, Abuja.
Ìpàdé tó bẹ̀rẹ̀ ní dédé agogo mẹ́rin ìrọ̀lẹ́, yóò dá lórí ìfọ̀rọ̀jomitoro ọ̀rọ̀…
Ìgbòkègbódò Ọkọ̀: Ìjọba Ìpínlè Ọ̀yọ́ Yan Alága Àti Akọ̀wé Ẹgbẹ́ ‘PMS’ Tuntun
Ìjọba Ìpínlè Ọ̀yọ́ labẹ àkóso Gómìnà Seyi Makinde tí yan Alhaji Oluwatomiwa Omolewa gẹgẹ bíi Alága tuntun fún Ìgbìmò to n ṣàkóso Ibùdókọ̀ (PMS).
Bákan náà ní ìjọba yan Alhaji Kasali Ajisafẹ, ti wọn mọ sí 'Baba Bola' gẹgẹ bíi Akọwe ẹgbẹ́.…
Agbófinró da àwọn òṣìṣẹ́ síta láti fòpin sí àṣẹ kónílé ó gbélé IPOB
Kọmíṣọ́nà Agbófinró ti ìpínlẹ̀ Enugu , Ọ̀gbẹ́ni Ahmed Ammani, ti da àwọn òṣìṣẹ́, àwọn ohun èlò ìṣiṣẹ́ àti ti ìṣiṣẹ́ ọpọlọ láti pèsè ààbò, ní ọjọ́ Ajé àti gbogbo ọjọ́ ní ìpínlẹ̀ náà.
Eléyìí wá lẹ́yìn àṣẹ…
Ẹ má ṣiyè méjì lórí Tinubu, Okechukwu rọ ọmọ Nàìjíríà
Aĺáṣẹ àpapọ̀, Voice of Nigeria (VON), Ọ̀gbẹ́ni Osita Okechukwu, ti rọ àwọn ọmọ Nàìjíríà láti ní ìgbàgbọ́ nínú ààrẹ Bọla Tinubu, fún àtúnṣe ipò ìbáraeniṣepọ̀ ọrọ̀ Ajé Nàìjíríà.
Ọgbẹni Okechukwu, oludasilẹ ọmọ…
A Ní Láti Bẹrẹ Ìgbésẹ̀ Àtúnṣe Ẹgbẹ́ Òṣèlú PDP Báyìí: Makinde Sọ Fún Àwọn Èèkàn Ẹgbẹ́
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Òyó Seyi Makinde tí ké sí gbogbo àwọn èèkàn ti ọrọ Ẹgbẹ́ Òṣèlú PDP jẹ lógún láti gbàgbé ìkùnsínú àtẹ̀yìnwá, ki wọn ṣetán láti ṣe àtúnṣe, ki wọn sì ṣiṣẹ papọ̀ fún iṣọkan ẹgbẹ́ náà.
Àtẹ̀jáde kan tí Akọwe ìròyìn fún Gómìnà,…
Ilé Aṣòfin Èkó fọwọ sí ọ̀pọ̀lọpọ̀ Àbádòfin àti Ìpinnu nínú sáà kẹsàn-án Ilé…
Oludari Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Mudashiru Ọbasa sọ ọ di mimọ ní Gbọgan Ile Aṣofin naa pe, awọn ti sọ abadofin mẹrindinlaadọta (46) di ofin, nigba ti awọn ti fọwọ si ipinnu to le ni ọgọfa (120) ati igbekalẹ…
Ìpínlẹ̀ Anambra : Igbákejì ọ̀gá Agbófinró fi ìrànlọ́wọ́ rẹ̀ dá àwọn agbègbè lójú
Igbákejì ọ̀gá Agbófinró, AIG, Ọ̀gbẹ́ni Tony Olofu tí ó ń ṣojú olú ilé-iṣẹ́ agbègbè kẹtàlá, ní Ukpo, ìpínlẹ̀ Anambra, ti fi dá àwọn agbègbè ní ìpínlẹ̀ náà lójú pé òun yóò ṣèrànlọ́wọ́ fún wọn.
AIG ṣe…
Gómìnà ìpínlẹ̀ Taraba: Ètò ẹ̀kọ́ jẹ wá lógún
Gómìnà Agbu Kefas ti Taraba, ti ṣe ìkéde pàjáwìrì lórí ètò ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ àti gíga ní ìpínlẹ̀ náà.
Ó ṣe ìkéde yìí níbi ìbáraẹnisọ̀rọ̀ pẹ̀lú àwọn akọ̀ròyìn ní ọjọ́ Àbámẹ́ta,ní Jalingo,…
Gómìnà Yan Àwọn Ikọ̀ Láti Se Ìwádìí Ọjà Òògùn Tó Jóná Ní Ìlú Onitsha
Gómìnà ìpínlẹ̀ Anambra, Ọ̀jọ̀gbọ́n Chukwuma Charles Soludo ti yan ikọ̀ ẹni mẹ́sàn án láti se ìwádìí ìṣẹ̀lẹ̀ iná tí ó wáyé ní ọjà oygùn (Ogbogwu) Onitsha, ní ọjọ́ Kejì oṣù kọkànlá, ọdún 2022.
Iná náà gba ẹ̀mí ènìyàn Mọ́kànlá, o…
Àjọ IoD Gba Àwọn Ọ̀gá Àgbà Ilé-isé Ní Ìmọ̀ràn Láti Máa Gbé Ìgbé Ayé Ìlera Pípé
Àjọ Institute of Directors (IoD), ti Nàìjíríà ti rọ àwọn ọ̀gá àgbà Ilé-isé láti máa ṣe Eré ìdárayá bí gbígba bọọlu gọ́ọ̀fù kí wọ́n leè má wà ni ìlera pípé ní ìgbà gbogbo.
Ààrẹ IoD, Dókítà Ije Jidenma, tí Alhaji Tijjani Borodo…