Take a fresh look at your lifestyle.
Browsing Category

ÌRÒYÌN ÌDÓKOÒWÒ

This is a category for business news

Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ṣe Ètò Láti Mú Ki Ọ̀gbìn Iṣu gbòrò Sí 

Ìjọba Nàìjíríà ti ṣí Ètò Ìdàgbàsókè láti mú kí ìṣẹ́ àgbẹ̀ tí ni gbórò sí pàápàá jùlọ ọgbin isu láti ìwọ̀n tọ́ọ̀nù mẹ́wàá sí ìwọ̀n tọ́ọ̀nù mẹ́ta fún hektari kan. Ètò náà jẹ́ ara ètò ìyípadà iṣẹ́ àgbẹ̀ tí a ṣe láti mú kí owó ìṣẹ́ àgbẹ̀ tu…

Àwọn Olùwakùsà Yanrìn Ń Wá Kí Ìjọba Tán Ìmọ́lẹ̀ Sí Òfin Lórí Odò ‘Niger’

Àwọn Òṣìṣẹ́ ní ẹ̀ka iwakùsà yanrìn odò ní Nàìjíríà ti rọ Àjọ 'National Inland Waterways Authority (NIWA)' láti ṣé ìtọ́sọ́nà lórí òfin àti ìlànà lórí odò Niger, wọ́n ṣàfihàn òfin onígbá méjì ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ láti ọ̀dọ̀ Ìjọba àpapọ̀ àti tí ìpínlẹ̀…

Ìlú Ìbàdàn Yóò Fọwọ́sowọ́pọ̀ Pẹlú Ilé Ẹ̀kọ́ Ìwádìí Ògbìn Kòkó Ni Orílẹ̀ Èdè Nàìjíríà (CRIN) Fún…

Nínú ìpinnu rẹ̀ láti mú ìdàgbàsókè dé bá ọrọ̀ ajé àti ìgbéga okòwò, Olúbàdàn ilẹ Ìbàdàn, Ọba Rashidi Adewolu Ladoja, Arusa I ti ké sí ilé ẹ̀kọ́ ìwádìí ọ̀gbìn Kòkó ni Orilẹ èdè Nàìjíríà (Cocoa Research Institute of Nigeria, CRIN) láti jíròrò…

Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Pẹ̀lú Orílẹ̀ Èdè Netherlands Fọwọ́sowọ́pọ̀ Lórí Ọ̀gbìn Tòmátò Pẹ̀lú Ìmọ̀ Ẹ̀rọ…

Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti gúnlè ṣíṣe àmúlò anfààní ìmọ̀ ẹ̀rọ aláìlééfín láti ṣe ogbin Tòmátò lọ́pọ̀ yanturu pẹ̀lú Orílẹ̀ Èdè Netherlands. Ẹni tíì ṣe Alákòóso àgbà ilé Àjọ Ìdàgbàsókè Òkòwò Iṣẹ́ Àgbẹ̀ ni Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ (Oyo State Agribusiness…
button