Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌDÓKOÒWÒ
This is a category for business news
Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ṣe Ètò Láti Mú Ki Ọ̀gbìn Iṣu gbòrò Sí
Ìjọba Nàìjíríà ti ṣí Ètò Ìdàgbàsókè láti mú kí ìṣẹ́ àgbẹ̀ tí ni gbórò sí pàápàá jùlọ ọgbin isu láti ìwọ̀n tọ́ọ̀nù mẹ́wàá sí ìwọ̀n tọ́ọ̀nù mẹ́ta fún hektari kan.
Ètò náà jẹ́ ara ètò ìyípadà iṣẹ́ àgbẹ̀ tí a ṣe láti mú kí owó ìṣẹ́ àgbẹ̀ tu…
Ààrẹ Tinubu Ṣe Ìdánilójú Ààbò Fún Àwọn Ọmọ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu ti fi dá àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lójú pé ìjọba rẹ̀ yóò máa rí àwọn àǹfààní tí a kọ sílẹ̀ nínú ìgbógunti tí ìwà ọ̀daràn, jíjí ènìyàn gbé àti àwọn ìwà ọ̀daràn mìíràn káàkiri orílẹ̀-èdè náà.
Ó fún wọn ní…
Àwọn Olùwakùsà Yanrìn Ń Wá Kí Ìjọba Tán Ìmọ́lẹ̀ Sí Òfin Lórí Odò ‘Niger’
Àwọn Òṣìṣẹ́ ní ẹ̀ka iwakùsà yanrìn odò ní Nàìjíríà ti rọ Àjọ 'National Inland Waterways Authority (NIWA)' láti ṣé ìtọ́sọ́nà lórí òfin àti ìlànà lórí odò Niger, wọ́n ṣàfihàn òfin onígbá méjì ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ láti ọ̀dọ̀ Ìjọba àpapọ̀ àti tí ìpínlẹ̀…
Àjọ NMDPRA Ti Ilé Epo Pa Látàri Ìwà Màgòmágó
Àjọ, The Nigeria Midstream and Downstream Petroleum Regulatory Authority (NMDPRA), ti ti ilé epo pa ní ilu
Port Harcourt ipinlẹ Rivers látàri ìwà màgòmágó sì epo Pẹntiróòlù -Premium Motor Spirit (PMS).
Nígbàtí ó ní sọrọ nibi…
Nàìjíríà Tún Ìpinnu Rẹ̀ Ṣe Láti Mú Ìrọ̀rùn Bá Iṣòwò
Mínísítà fún Ìròyìn àti Àlàyé Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Mohammed Idris, ti tún ìpinnu Ìjọba Àpapọ̀ ṣe láti mú ìrọ̀rùn bá ṣíṣe iṣòwò, àìsí ìrújú kan àti àtúnṣe àwọn ilé-iṣẹ́ ìṣòwò, ó ṣàpèjúwe ìfọwọ́sowọ́pọ̀ tó munadoko láàárín àwọn ilé-iṣẹ́…
UNICEF, Standard Charted Yóò Wá’ṣẹ Fún Àwon Ọmọ Obìnrin Ẹgbẹ̀rún Kan Àbọ̀
Standard Chartered Foundation àti Àjọ UNICEF’s Generation Unlimited (UNICEF GenU) ti kéde àjọṣepọ̀ láti ran àwọn obìnrin ẹgbẹ̀rún-kan-àbọ̀ ọ̀dọ́ lọ́wọ́ láti rí iṣẹ́ tó dára ní Kenya àti Nàìjíríà.
Ajọṣepọ ọdún mẹ́ta náà yóò dojúkọ àwọn…
Minisita Bẹ̀rẹ̀ Ìlànà Ìmúṣẹ fún Àdéhùn Àlàáfíà Àwùjọ Nàìjíríà àti Türkiye
Minisita fún Ọ̀rọ̀ Àwọn Obìnrin àti Ìdàgbàsókè Àwùjọ Nàìjíríà, Imaan Sulaiman-Ibrahim, ti ṣe ìpàdé gíga pẹ̀lú Minisita fún Ìdílé àti Àwọn Iṣẹ́ Àwùjọ ti Türkiye, Mahinur Özdemir Göktaş láti bẹ̀rẹ̀ ìmúṣẹ àwọn àdéhùn lórí ìṣọ̀kan Ìdílé àti…
Ìlú Ìbàdàn Yóò Fọwọ́sowọ́pọ̀ Pẹlú Ilé Ẹ̀kọ́ Ìwádìí Ògbìn Kòkó Ni Orílẹ̀ Èdè Nàìjíríà (CRIN) Fún…
Nínú ìpinnu rẹ̀ láti mú ìdàgbàsókè dé bá ọrọ̀ ajé àti ìgbéga okòwò, Olúbàdàn ilẹ Ìbàdàn, Ọba Rashidi Adewolu Ladoja, Arusa I ti ké sí ilé ẹ̀kọ́ ìwádìí ọ̀gbìn Kòkó ni Orilẹ èdè Nàìjíríà (Cocoa Research Institute of Nigeria, CRIN) láti jíròrò…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Pẹ̀lú Orílẹ̀ Èdè Netherlands Fọwọ́sowọ́pọ̀ Lórí Ọ̀gbìn Tòmátò Pẹ̀lú Ìmọ̀ Ẹ̀rọ…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti gúnlè ṣíṣe àmúlò anfààní ìmọ̀ ẹ̀rọ aláìlééfín láti ṣe ogbin Tòmátò lọ́pọ̀ yanturu pẹ̀lú Orílẹ̀ Èdè Netherlands.
Ẹni tíì ṣe Alákòóso àgbà ilé Àjọ Ìdàgbàsókè Òkòwò Iṣẹ́ Àgbẹ̀ ni Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ (Oyo State Agribusiness…
Ilé-iṣẹ́ ‘Galaxy Backbone’ Tí Ṣetán Lati Ṣayẹyẹ Ogún Ọdún
'Galaxy Backbone Limited' (GBB), ilé-iṣẹ́ Ayélujára tó ga jùlọ ní Nàìjíríà àti olùpèsè iṣẹ ayélujára tí Ìjọba Àpapọ̀ tí kéde ayẹyẹ ogún ọdún ilé-iṣẹ́ náà tí yóò wáyé ní Oṣu Kẹfa ọdún 2026.
Èyí ni a sọ ninu atẹjade kan ti Olori Ìròyìn…