Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌDÓKOÒWÒ
This is a category for business news
Nàìjíríà Ṣé Ìfilọ́lẹ̀ Ibùdó Ìtajà Fáàárí Ńlá Ni Borno L’ójúnà Látí Pèsè Iṣẹ́
Ìjọba Nàìjíríà tí ṣé ìfilọ́lẹ̀ ọjà fáàárí nlá kán ni Maiduguri, Olú-ìlú Ìpínlẹ̀ Borno, pẹ̀lú afojusun látí pèsè iṣẹ́ tó fẹ́ tó ẹgbẹ̀rún àádọ́ta nípasẹ ilé-iṣẹ́ náà.
Ní ìtẹ̀síwájú àtìlẹ́yìn tí oní bílíọ̀nù márùn-dín-lọgọ́rin (N75b)…
Nàìjíríà Fẹ́ Àtìlẹ́yìn Bánkì Àgbáyé Fún Ẹ̀ka Ètò Irin
Ìjọba Nàìjíríà nípasẹ Mínísírì ìdàgbàsókè irin ti ń wá ìrànwọ́ Bánkì Àgbáyé fún ìrànlọ́wọ́ ìdàgbàsókè irin tútù àti àwọn nǹkan míràn tó so mọ́ ìtẹ̀síwájú ẹ̀ka irin tútù ní orílẹ̀-èdè yìí.
Mínísítà ìdàgbàsókè irin ni orílẹ̀-èdè…
Ẹ Se Àtìlẹyìn Fún Ààrẹ Tinubu Láti Mú Ìdàgbàsókè Aláìlẹ́gbẹ́ Bá Ètò Ọrọ̀ Ajé-…
Wọ́n ti pàrọwà sí àwọn alẹ́nulọ́rọ̀ láti se àtìlẹyìn fún Ààrẹ Bọla Tinubu lórí àtúntò ètò ọrọ̀ ajé èyí tí yóò mú ìdàgbàsókè bà ọrọ̀ ajé àti Orílẹ̀-èdè lápapọ̀
Mínísítà Fuń Ohun…
Ìlàkààkà Ààrẹ Tinubu Láti Mú Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Dé Ilẹ̀ Ìlérí Ń So Èso Rere-…
Mínísítà Fún Ohun Àlùmọ́ọ́nì, Ọ̀gbẹ́ni Dele Alake àti Gomina Ìpínlẹ̀ Kaduna Uba Sani ti sàpèjúwe ìgbésẹ̀ ìsèjọba Ààrẹ Bọla Tinubu gẹ́gẹ́ bí èyí tí yóò mú ìyípadà ọ̀tun bá Orílẹ̀-èdè, tí yóò sì sọ ayé…
Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ní Ohun Àmúyẹ Fún Ìdàgbàsókè Ọrọ̀ Ajé: Igbákejì Ààrẹ…
Ìjọba Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti késí àwọn olùdókòwò ilẹ̀ òkèèrè láti darapọ̀ mọ́ ètò ọrọ̀ ajé Orílẹ̀-èdè náà èyí tí ó ti ń rú gọ́gọ́ sí i, èyí tí yóò mú ìgbòòrò bá ìdókòwò wọn àti ọrọ̀ ajé…
Ìbásepọ̀ Tí Ó Múná Dóko Wáyé Láàrin Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Àti Botswana
Igbákejì Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Naijiria, Kashim Shettima ti sèpàdépọ̀ pẹ̀lú Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Botswana, Duma Boko, èyí tí ó wáyé ní Davos, Orílẹ̀-èdè Switzerland, níbi tí wọ́n ti ní ìfẹnukò lórí àwọn ohun tí yóò…
Iréwọlédé, Ẹ Máa Jó Jàgíní-yòdò: Ìjọba Àpapọ̀ Sàgbékalẹ̀ Ilé Iṣẹ́ Fún Ẹ̀yáwó Láti…
Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu ti sàdéhùn láti mú ìdàgbàsókè bá ìgbáyégbádùn ọmọ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà pẹ̀lú ìsàgbékalẹ̀ ilé iṣẹ́ ètò ẹ̀yáwó
Ìgbésẹ̀ náà wáyé láti mú ìgbòòrò bá ẹka ètò…
Ìdùnnú Subú Lu Ayọ̀ Ní Ìlú Abuja Nígbà Tí Ààrẹ Tinubu Ń Pín Oúnjẹ Fún Àwọn…
Ariwo ayọ̀ ń jáde lẹ́nu àwọn ènìyàn nígbà tí Mínísítà Fún Ọ̀rọ̀ Àwọn Obìnrin, Ọnọrébù Imaan Sulaiman-Ibrahim ń pín oúnjẹ fún àwọn Obìnrin ní Ìlú Abuja, èyí tí ó wà lára ètò àlàkalẹ̀ fún ayẹyẹ ìparí…
Ọ̀wọ́ngógó Owó Ọjà Yóò Di Àfìsẹ́yìn Tí Egúngún Ń Fi Aṣọ Ní Ọdún 2025- Ààrẹ Sọ̀rọ̀…
Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu fi àrídájú hàn pé Òun yóò mú àdíkù bá fífi ọ̀pọ̀lọpọ̀ owó ra ọjà kékeré ti o n waye ni Orilẹ-ede Naijiria láti ìdá mẹ́rìnlélọ́gbọ̀n nínú ọgọ́rùn-ún (34%) sí ìdá mẹ́ẹ̀dóógún nínú…
Ẹ Gbọ́lá Fún Àwọn Ohun Èlò Tiwa-n-tiwa: Ìjoba Àpapò Pàrọwà Sí Ará Ìlú
Ìjọba àpapọ̀ ti sàlàyé pàtàkì rírà àti bíbu ọlá fún àwọn ohun èlò tiwa-n-tiwa, lójúnà àti mú ìdàgbàsókè bá ètò ọrọ̀ ajé Orílẹ̀-èdè Naijiria
Ìpè náà wáyé láti ọ́ọ́fìsì akọ̀wé ìjọba…