Take a fresh look at your lifestyle.
Browsing Category

ÌRÒYÌN ÌDÓKOÒWÒ

This is a category for business news

Nàìjíríà Ṣé Ìfilọ́lẹ̀ Ibùdó Ìtajà Fáàárí Ńlá Ni Borno L’ójúnà Látí Pèsè Iṣẹ́ ‎

Ìjọba Nàìjíríà tí ṣé ìfilọ́lẹ̀ ọjà fáàárí nlá kán ni Maiduguri, Olú-ìlú Ìpínlẹ̀ Borno, pẹ̀lú afojusun látí pèsè iṣẹ́ tó fẹ́ tó ẹgbẹ̀rún àádọ́ta nípasẹ ilé-iṣẹ́ náà. ‎ ‎ Ní ìtẹ̀síwájú àtìlẹ́yìn tí oní bílíọ̀nù márùn-dín-lọgọ́rin (N75b)…

Ìlàkààkà Ààrẹ Tinubu Láti Mú Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Dé Ilẹ̀ Ìlérí Ń So Èso Rere-…

Mínísítà Fún Ohun Àlùmọ́ọ́nì, Ọ̀gbẹ́ni Dele Alake àti Gomina Ìpínlẹ̀ Kaduna Uba Sani ti sàpèjúwe ìgbésẹ̀ ìsèjọba Ààrẹ Bọla Tinubu gẹ́gẹ́ bí èyí tí yóò mú ìyípadà ọ̀tun bá Orílẹ̀-èdè, tí yóò sì sọ ayé…

Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ní Ohun Àmúyẹ Fún Ìdàgbàsókè Ọrọ̀ Ajé: Igbákejì Ààrẹ…

Ìjọba Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti késí àwọn olùdókòwò ilẹ̀ òkèèrè láti darapọ̀ mọ́ ètò ọrọ̀ ajé Orílẹ̀-èdè náà èyí tí ó ti ń rú gọ́gọ́ sí i, èyí tí yóò mú ìgbòòrò bá ìdókòwò wọn àti ọrọ̀ ajé…

Iréwọlédé, Ẹ Máa Jó Jàgíní-yòdò: Ìjọba Àpapọ̀ Sàgbékalẹ̀ Ilé Iṣẹ́ Fún Ẹ̀yáwó Láti…

Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu ti sàdéhùn láti mú ìdàgbàsókè bá ìgbáyégbádùn ọmọ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà pẹ̀lú ìsàgbékalẹ̀ ilé iṣẹ́ ètò ẹ̀yáwó Ìgbésẹ̀ náà wáyé láti mú ìgbòòrò bá ẹka ètò…

Ọ̀wọ́ngógó Owó Ọjà Yóò Di Àfìsẹ́yìn Tí Egúngún Ń Fi Aṣọ Ní Ọdún 2025- Ààrẹ Sọ̀rọ̀…

 Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu fi àrídájú hàn pé Òun yóò mú àdíkù bá fífi ọ̀pọ̀lọpọ̀ owó ra ọjà kékeré ti o n waye ni Orilẹ-ede Naijiria láti ìdá mẹ́rìnlélọ́gbọ̀n nínú ọgọ́rùn-ún (34%) sí ìdá mẹ́ẹ̀dóógún nínú…
button