
Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌDÓKOÒWÒ
This is a category for business news
Ìgbèrú Yóò Débá Ọrọ̀ Ajé Wa Tí A Bá Dá Ọjà Ìsẹ̀mbáyé Sílẹ̀ Ti A ÓÒ Leè Máa Kó Nǹkan Lọ Sí Ìlú Òkèèrè…
Gómìnà Chukwuma Charles Soludo ti ìpínlẹ̀ Anambra ti sọ wi pé tí wọ́n bá dá ọjà Ìsẹ̀mbáyé sílẹ̀ tí wọn óò ti máa kó ọjà lọ sí Ìlú Òkèèrè sí àgbègbè Dunukofia yóò mú kí ọrọ ajé Ìpínlẹ̀ náà gbèrú síi.
Gómìnà sọ èyí ní ìgbà tó ń…
Ẹ̀ka Ọkọ̀ Òfurufú Nàìjíríà Gbà Owó Tó Lé Ní Ọ̀ọ́dẹ́gbẹ̀rin Mílíọ̀nù Náírà Fún Ìtọ́jú Pápákọ̀
Ilé-iṣẹ́ Òfurufú tí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ní Ọjọ́rú gbá ibuwọlú ìwé iṣẹ́ àkànṣe tí ó tó ọ̀ọ́dẹ́gbẹ̀rin lé lógún mílíọ̀nù Náírà N721m fún ìtọ́jú Pápákọ̀ Òfurufú Aminu Kano International ní Ìpínlẹ̀ Kano, Àríwá Ìwọ̀-oòrùn tí orílẹ̀-èdè yìí tí…
Àjọ Tí Ó Ń Gbógun Ti Ìwà Ìbàjẹ́ Sàwárí Ọ̀ọ́dúnrún Mílíọ̀nù Owó Tuntun Ní Ilé…
Àjọ tí ó ń gbógun ti ìwà ìbàjẹ́ àti ìwà búburú míràn ti se àwárí ọ̀ọ́dúnrún mílíọ̀nù ó dín díẹ̀ owó tuntun èyí tí wọ́n kó pamọ́ ní ọ́ọ́fìsì àpapọ̀ ilé ìfowópamọ́ Sterling ní ìlú Abuja.
…
Ẹ fi owó Náírà tuntun síta fún àwọn ará ìlú
Gómìnà ìpínlẹ̀ Kwara, AbdulRahman AbdulRazaq ti pè fún ìpèsè owó Náírà tuntun síta jákèjádò orílẹ̀-èdè fún ìrọ̀rùn títà-rírà àwọn ará ìlú àti ìfẹsẹ̀múlẹ̀ ìlànà ìpààrọ̀ owó.
Nígbà tí ó ń…
Ẹ́ Fí Àyè Gbá Àwọn Aṣojú-Owó Látí Wá Ojútùú Sí Owó Tuntun – Ìgbákejì Ààrẹ Pàrọ̀wá Fún Àwọn…
Ọnà sí ìṣòro tí àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ń kojú lórí owó tuntun ní kí Bánkì gbogbogbò orílẹ̀-èdè yìí (Central Bank of Nigeria CBN) àtí àwọn Bánkì Ìṣòwò (Commercial Banks) fí ayé púpọ̀ díẹ̀ síì gbà àwọn aṣojú owó àti FinTech látí kojú…
Orílẹ̀ Èdè France Se Ìrànlọ́wọ́ Owó Fún Ìdàgbàsókè Ètò Ọ̀gbìn Ní Nàìjíríà
Ìjọba orílẹ̀ èdè France ti mú ìgbòòrò bá ètò ọ̀gbìn ní orílẹ̀ èdè Nàìjìríà pẹ̀lú pípèsè owó tí ó lé mílíọ̀nù kan owó ilẹ̀ òkèèrè (1.2m Euro). Èyí tí ìrètí wà pé yóò mú àlékún bá ìpèsè…
Ààrẹ Buhari Gbé Ìgbésẹ̀ Akin Lórí Ọ̀wọ́n-gógó Owó
Ààrẹ Buhari pàrọwà sí gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà láti fún òun ní ọjọ́ méje kí ó fi yanjú ìsòro ọ̀wọ́n-gógó owó, èyí tí ó ti dá awuyewuye sílẹ̀ jákè-jádò orílẹ̀ èdè.
Ó fi ọ̀rọ̀ náà léde…
Owó Tuntun Yóò Jáde Lọ́pọ̀ Yanturu- Ààrẹ Fi Àrídájú Léde
Ààrẹ Buhari ti fi àrídájú hàn pé ètò owó tuntun kò ní kó ìpalára bá ọrọ̀ ajé àti ìgbáyégbádùn mùtúmùwà.
Ó sọ ọ̀rọ̀ náà láti le è tu àwọn ènìyàn nínú látàrí wàhálà àti ọ̀pọ̀lọpọ̀…
Ẹgbẹ́ Àwùjọ Aráàlú Kàn Bẹ̀rẹ̀ Abojuto Àwọn Bánkì Pẹ̀lú Ìlànà CBN Lórí Owó Tuntun
Ẹgbẹ́ àwùjọ aráàlú kàn, National Coalition On Improved Service Delivery (NACOISED) sọ pé òun tí ṣètò látí bẹ̀rẹ̀ abojuto àwọn bánkì ní ìbámu pẹ̀lú àṣẹ àtí ìlànà CBN látí ríi dájú pé àwọn ẹrọ ATM wọ́n ń pọ́ owó 200, 500 àtí 1000 tuntun…
Orílè-èdè Senegal Gbà Àlejò Ààrẹ Nigeria Fún Àpéjọ Tó Dá Lórí Ìṣẹ́-Ọ̀gbìn
Ààrẹ Muhammadu Buhari tí dé sí Dakar, Olú-ìlú Senegal, lori àpéjọ ẹlẹẹkeji irú rẹ̀, tí "Dakar International Conference on Agriculture."
Ààrẹ Buhari ló fí ìlú Èkó sílẹ̀ lọ́ sí orílẹ̀-èdè Senegal lọ́jọ́ Ìṣẹgun lẹ́yìn àbẹ̀wò oníṣẹ́…