Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌDÓKOÒWÒ
This is a category for business news
Ilé-iṣẹ́ Sìmẹ́ńtì Dangote : Ọjà yóò wà káàkiri lárọwọ́tó Àwọn fún ọmọ Nàìjíríà
Ilé-iṣé Sìmẹ́ńtì Dangote ti fi dá àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lójú pé ọjà yóò wà lọ́pọ̀ àti lárọwọ́tó wọn,pàápàá jùlọ lásìkò yìí tí ó ń jinlẹ̀ si láti ṣe dééd́éé lórí ọjà rẹ̀ àti títàn si.…
Àwọn aṣojú tí ó ní ìwé-àṣẹ nìkan ni yóò le ra ọjà tààrà láti ọ̀dọ̀ àwọn àgbẹ̀…
Ìgbìmọ̀ Aláṣẹ àpapọ̀ (FEC) ti fọwọ́sí pé àwọn aṣójú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà nìkan tí ó ní ìwé-àṣẹ ni yóò le ra ọjà tààrà láti ọ̀dọ̀ àwọn àgbẹ̀ àti títà fún àwọn àjèjì.
Ifọwọsi yii waye nibi ipade …
Ìjọba Àpapọ̀ Bu Ọwọ́ Lu Àdéhùn (MOU) Pẹ̀lú Ilé-Iṣẹ́ Huawei Technologies Nigeria Limited…
Ìjọba àpapọ̀ àti ilé-iṣẹ́ Huawei Technologies Nigeria Limited ti fọwọ́ sí ìwé àdéhùn kan (MoU) lórí Ìmọ̀-ẹ̀rọ Ìbáraẹnisọ̀rọ̀ (ICT) láti ṣe ìdánilẹ́kọ̀ọ́ àti ìdánilókòwò fun ẹgbẹrun òsìsẹ́ ìjọba jakejado orilẹ…
ECOWAS Kọ Ìṣètò Ìṣèjọba Ològun ní Málì, Fi òfin dèé
Lẹ́hìn àgbéyẹ̀wò ọ̀rọ̀ orílẹ̀-èdè Málì níbi Àpèjọ pàtàkì kan ní́ ọjọ́ àìkú, àwọn olùdárí Àwùjọ Ìṣòwò ti Ihà iwọ̀-oòrùn Adúláwọ̀, ECOWAS, kọ ìgbésẹ̀ ìṣètò ìyíjọba padà sí ológun Málì, ó sọ…
Ilé-ìfowópamọ́ JAIZ sọwọ́ ọjà wọn sílẹ̀ fún ìtẹ́wọ́gbà Ìgbélárugẹ…
Ilé ìfowópamọ́ Jaiz yóò tẹ̀síwájú láti ṣe ìdọ́gba gbígba ọjà rẹ̀ àti ìsọdọ̀tun láti ri pé ó ní oníbàárà tí ó pọ̀ jùlọ nígbà gbogbo.
Gẹgẹ bi o ti sọ, lati iwọn iwọntunwọnsi bilionu mejila Naira ni ọdun 2012,…
ètò ìdìbò 2023:N kò ní àyànfẹ́ kankan tí yóò gba ipò mi-Ààrẹ Buhari
Ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà , Muhammadu Buhari ti ní òun kò ní ẹnìkankan lọ́kàn tí yóò gba ipò rẹ̀ nínú ètò ìdìbò tí yóò wáyé lẹ́yìn ìgbà tí ó bá fi àlèéfà sílẹ̀ lọ́dún 2023.
Aarẹ Buhari sọrọ…
A O San Sokoto Wa Lati Wu Awon Oludasilẹ Ile-isẹ Lori
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti fi dá ajọ awọn oludasilẹ ile-isẹ ti Nàìjíríà (MAN) lójú pé ijọba Nàìjíríà yóò gbé àwọn ìgbésẹ̀ tó yẹ láti mú kí àyè gba lilo owó ilẹ̀ okèèrè fún gbígbé àwọn ohun èlò àti ẹ̀rọ tí kò sí ni Naijiria wole.
O ṣe…
Ààrẹ Bùhárí ń bèèrè fún ìfọkàntán Lórí ọwọ́ Àwọn ohun àlùmọ́ọ́nì
Mùhámmádù Bùhárí ti pàṣẹ fún Ààrẹ Artisanal Gold Mining Development Initiative (PAGMI) láti pèsè èsì oṣù mẹ́fà lórí owó ìdàgbàsókè ohun àlùmọ́nì,tí ó wà fún ìdíyelé ìdókòwò.
Ero ngba eyi ni lati rii…
NIDOE yóò Dá ibùjókòó ìdókòwò fún àwọn ọmọ Nàìjíríà tí wọ́n ń gbé ní òkè…
Ẹgbẹ́ Àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tó ń gbé lókè òkun (NIDOE), ẹ̀ka orílẹ̀-èdè Itali , sọ pé ó ń gbèrò láti kọ́ ọ̀pọ̀lọpọ̀ mílíónù dọ́là 'Diaspora Village' ní Nàìjíríà gẹ́gẹ́ ,bí ara àwọn…
Ìjọba Nàìjíríà Pín Owó tó tó Ọgọrun Bilionu Naira Fún Ìdásílẹ̀ Isẹ́
Ìjọba Nàìjíríà ti kéde pé òun ti pín ọgọ́rùn-ún bílíọ̀nù náírà láti fi dá iṣẹ́ sílẹ̀ fún àwọn ọ̀dọ́ àti láti kojú àìríṣẹ́ṣe tó ń gbòòrò sí i ní Nàìjíríà.
Eyi jade ninu atejade kan lati ọwọ Minisita fun iṣẹ, Ọgbẹni Festus Keyamo, SAN,…