Take a fresh look at your lifestyle.
Browsing Category

ÌRÒYÌN ÌDÓKOÒWÒ

This is a category for business news

Owó Orí Ọjà Amẹ́ríkà Dẹ́rùba Ọrọ̀ Ajé Ilẹ̀ Adúláwọ̀ -Akọ́sẹ́mọsẹ́ Ọmọ Orílẹ̀-èdè Màláwì

Owó orí ọjà Amẹ́ríkà lórí ọrọ̀ ajé ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè ilẹ̀ Adúláwọ̀ sàkóbá bá ọrọ̀ ajé wọn, orílẹ̀-èdè Màláwì jẹ́ ọ̀kan, akọ́sẹ́mọ́sẹ́ nípa ọ̀rọ̀ òṣèlú-Maclan Kanyang’wa sọ èyí. Ó sọ pé, oye owó tí wọ́n ń ta nǹkan ní…

Aṣòfin Oluremi Tinubu Pé Fún Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ Olori Ìlú Láti Fòpin Sí Dídá Abẹ Fún Ọmọbìnrin (FGM)

Àyà Ààrẹ Orilẹ Èdè Nàìjíríà, Aṣòfin Oluremi Tinubu ti ké sí àwọn Olórí ìlú àti agbègbè láti sa ipá wọn lójúnà àti fi òpin sí dídá abẹ fún ọmọ obìnrin (FGM), kòkòrò HIV/AIDS àti àrùn jẹ̀dọ̀jẹ̀dọ̀. Oluremi Tinubu lo fi ọ̀rọ̀ lédè lásìkò tó…

Ààrẹ Bola Tinubu tí kí Ààrẹ Ẹgbẹ́ Dangote, Alhaji Aliko Dangote, lórí yíyàn rẹ̀ sí ilé-iṣẹ́ ìdókòwò…

Ààrẹ Bola Tinubu tí kí Ààrẹ Ẹgbẹ́ Dangote, Alhaji Aliko Dangote, lórí yíyàn rẹ̀ sí ilé-iṣẹ́ ìdókòwò aládàáni ti banki àgbáyé. ‎ ‎ Ilé-iṣẹ́ Ìdókòwò Aládàáni tí Bánkì Àgbáyé jẹ́ 'apá kán tó níí ṣé pẹ̀lú ìgbéga ìdókòwò àti ṣiṣẹda iṣẹ́ ní àwọn…

Makinde Ke Sí Ọmọ Orílẹ̀ Èdè Nàìjíríà Láti Wá Dá Okòwò Sílẹ̀ Ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti ké sí ọmọ Orílẹ̀ Èdè Nàìjíríà láti wá da okòwò sílẹ̀ ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, nígbà tó fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé Ìpínlẹ̀ náà wà lójú iṣẹ́ lójúnà àti mú kí ọrọ̀ àjé gbèru síi nípasẹ̀ ètò ìgbáyé-gbádùn. Makinde ló fìdí…

Ìdókòwò Alábọ́dé Ni Ọ̀pákùtẹ̀lẹ̀ Ọrọ̀ Ajé Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà – Mínísítà Jumokẹ…

Mínísítà Fún Ilé Iṣẹ́, Òwò àti Ìdókòwò ti sàfirinlẹ̀ ipa tí ìsòwò alábọ́dé ńkó gẹ́gẹ́ bí ọ̀pákùtẹ̀lẹ̀ èyí tí ó ń mú ìdàgbàsókè bá ètò ọrọ̀ ajé Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà   Nígbà tí ó ń sọ̀rọ̀…
button