Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌDÓKOÒWÒ
This is a category for business news
ONSA Àtí CBN Ṣé Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ Látí Jẹ́ Kí Ètò Ọrọ̀-Àjé Múlẹ̀
Ilé-iṣẹ́ tí Oludamọran Ààbò fún Orílẹ̀-èdè (Office of the National Security Adviser ONSA) àtí Bánkì Àpapọ̀ tí Orílẹ̀-èdè (Central Bank of Nigeria CBN) tí darapọ̀ látí kojú àwọn ìpèníjà tí ètò-ọ̀rọ̀ àjé Orílẹ̀-èdè náà.
Ọrọ̀ náà tí…
Àwọn Ilé-iṣẹ́ Simẹnti Gbá Láti Ṣé Àdínkù Ìyè Owó Simẹnti Sí Ẹgbẹ̀rún Mẹ́jọ́
Àwọn Ilé-iṣẹ́ simẹnti tí gbá láti ṣé àdínkù ìdíyelé owó simẹnti látí ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá (N10,000) sí láàrin ẹgbẹ̀rún méje (N7,000) àtí ẹgbẹ̀rún mẹ́jọ́ (N8,000) fún àádọta Kilogiramu (50kg) tí ìjọba àpapọ̀ bá lè gbé àwọn ìgbésẹ̀ kàn.…
Ilé-ìgbìmọ̀ Aṣòfin Kóró Ójú Sí Bí Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ṣé Ń Pàdánù Owó-orí Tó Tó Tírílíọ̀nù…
Ilé-ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà tí Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, nípasẹ Ìgbìmọ̀ rẹ̀ lórí Ìṣúná ní òwúrọ̀ Ọjọ́ Ajé, bínú sí bí Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ṣé pàdánù Tírílíọ̀nù Mẹ́ta-Dín-Lógún (N17 trillion) láàrin ọdún márùn-ùn lórí amójú kúrò Owó-orí fún àwọn kàn.…
Ìbásepọ̀ Tí Ó Múná Dóko Yóò Wáyé Láàrin Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Àti Brazil
Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu sọ pé Nàìjíríà ti gbáradì láti ta kókó ìbásepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú Orílẹ̀-èdè Brazil
Ààrẹ sọ ọ̀rọ̀ náà nígbà tí ó pàdé Ààrẹ Luiz Inacio Lula da Silva ti Orílẹ̀-èdè Brazil, ní…
Òṣuwọn Oṣù Kínní Ṣàfihàn Ìwọ̀n 29.90 Nínú Ọgọrùn Gẹ́gẹ́bí Èle Orí Owó Ọjà
Òṣuwọn Oṣù Kìnní ọdún 2024 Ṣàfihàn Ìwọ̀n 29.90 nínú ọgọ́ọ̀rún gẹ́gẹ́bí èle orí owó ní àfiwé sí tí Oṣù Kejìlá ọdún 2023 èyí tó jẹ́ ìwọ̀n 28.92 nínú ọgọ́ọ̀rún.
Àgbéjáde Oṣù Kínní Ọdún 2024 CPI sọ pé àwọn Àjọ tó ń rí sí ìṣirò tí Nàìjíríà…
Ìforúkọsílẹ̀ Àwọn Olùdókoòwò Alábọ́dé Ti Bẹ̀rẹ̀ Ní Pẹrẹwu- Àjọ CAC Fi Ọ̀rọ̀ léde
Àjọ CAC ti bẹ̀rẹ̀ ìforúkọ sílẹ̀ fún àwọn olùdókoòwò alábọ́dé tí ó tó ẹgbẹ̀rún méjì gẹ́gẹ́ bí àlàkalẹ̀ òfin ìdókoòwò
Alákòóso àjọ náà, Hussaini Ishaq Magaji ni ó sísọ lójú ọ̀rọ̀ náà ní ọjọ́…
Ilé Ìfowópamọ́ Ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ti Dáwọ́ Sísan Owó Dọ́là Dúró
Ilé ìfowóráńsẹ́ ní àgbáyé àti ilé ìfowópamọ́ ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti dáwọ́ dúró nípa sísan owó dọ́là fún oníbáárà rẹ̀
Ìgbésẹ̀ náà wáyé látàrí ìfiléde kan tí báńkì àpapọ̀…
Ètò Ọrọ̀ Ajé Yóò Gbọ́pọn Sí i Láàrín Orílẹ̀-èdè Nàíjíríà Àti Angola
Bí Áfíríkà ṣe n tẹsiwaju lati wa àwọn ọna ti yóò gbé òwò àti ọrọ aje laruge laarin awọn ilẹ Afirika, Ọna lati koju awọn idena òwò ṣiṣe ati ṣiṣe awọn ilana iwe irinna, ti àwọn oloyinbo n pe ni Físà ni wọn fẹ ri daju pe wọn…
Àwọn ilé iṣẹ́ Indian fi Bílíọ̀nù mẹ́tàdín-lọ́gbọ̀n Dọ́là ṣe ìdókòwò nínú ọrọ̀ ajé…
Àádọ́jọ ilé iṣẹ́ India ló ti ṣe ìdókòwò pẹ̀lú Bílíọ́nù mẹ́tàdín-lọ́gbọ̀n Dọ́là ní Nàìjíríà.
Aṣoju India si Nàìjíríà, Ọgbẹni Gangadharan Balasubramanian sọ eyi ni Abuja nibi apejẹ alẹ lati ṣami ọdun…
Olùṣòwò British, John Lewis yóò da òṣìṣẹ́ ẹgbẹ̀rún mọ́kànlá sílẹ̀
Àjọṣepọ̀ John Lewis, tí ó ni John Lewis and Waitrose, ti ń gbèrò láti da àwọn ẹgbẹ̀rún òṣìṣẹ́ sílẹ̀ ní ọdún márùn ún tí ń bọ̀, ilé ìròyìn agbègbè ló sọ èyí.
O kere ju, ida mẹwaa ninu ida ọgọrun oṣiṣẹ ni yoo…