Ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, Muhammadu Buhari ti ní ìjọba òun ti se gudugudu méje , yàyà mẹ́fa láàrin ọdún mẹ́fà tí wọn ti wà lórí àlèéfà láti ṣe àtúnse tó gbóúnjẹ fẹ́gbẹ́, gbàwo bọ̀ lórí ètò ọrọ̀ ajé.
Aarẹ sọrọ yii lasiko to n ba gbogbo ọmọ orilẹ ede Naijiria sọrọ lori ẹrọ mohun-maworan , lati ṣe ami ayẹyẹ ajọdun ọdun mejilelogun eto ijọba tiwa-n-tiwa lorilẹ ede Naijiria
Aarẹ ni ìsẹ́ ati àínísẹ́ lo n fa a ti eto aabo orilẹ ede Naijiria se n wọ́lẹ̀ amosa, ijọba ti n gbe igbesẹ lati fopin ṣi isoro wọnyi.
Leave a Reply