Browsing Category
Ó GBÓNÁ FẸLI-FẸLI
This is a category for LATEST NEWS
Ààrẹ Tinubu kò fọwọ́ yẹpẹrẹ mú àìláábò tí ń kojú Ẹkùn, Àgbáyé
Mínísítà Nàìjíríà fún ìbáraẹnisọ̀rọ̀ àti ìṣàlàyè, Mohammed Idris, sọ pé Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu ti túnbọ̀ tẹra mọ́ ìpè fún àtìlẹyìn ẹkùn àti àgbáyé láti kojú àìláábò ní Nàìjíríà àti láti dá…
Ààrẹ Tinubu buwọ́lu iye owó tó ju tíríọ́nù mẹ́ta lọ fún sísan gbèsè ẹ̀ka iná
Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu ti buwọ́lu iye owó tó ju tíríọ́nù mẹ́ta lọ gẹ́gẹ́ bí owó àsantán gbèsè ọlọ́jọ́ pípẹ́ , tó wànílẹ̀ fún ìṣàtúnṣe ní ẹ̀ka iná Nàìjíríà.
Alaye kan ti oludamọran pataki fun Aarẹ, Ọgbẹni Bayọ…
Minisita Russia Kan Bá Akẹgbẹ́ Egypti Rẹ̀ Sọ̀rọ̀
Minisita Russia fun Oro ilẹ̀ Ajeji, Sergey Lavrov ba akẹgbẹ Egipiti, Badr Abdelatty sọrọ ní Moscow ni ọjọ Ẹti.
Ipade wọn dojukọ lori mimu awọn ibatan meji laarin Russia ati Egypt lagbara, ati atunyẹwo awọn ọran pataki lori ọrọ…
Mínísítà Ìpínlẹ̀ Fún Iṣẹ́ Àti Ìgbanisisẹ́ Ti Kọ̀wé Fipò Sílẹ̀
Mínísítà Ìpínlẹ̀ fún Iṣẹ́ àti Ìgbanisisẹ́ Nàìjíríà, Nkeiruka Onyejeocha, ti kọ̀wé fipò rẹ silẹ.
Nigbati o kede ifisẹ́silẹ rẹ lori ayelujara "X" rẹ, Minisita naa fi ọpẹ fun Aare Bola Ahmed Tinubu fun anfani lati ṣiṣẹ ninu…
Àjọ UN Gbé Àníyàn Soke Látàrí Bí Burkina Faso Ṣe Ń Fi Àyípadà Falẹ̀
Àjọ Àgbáyé ti fi àníyàn hàn lórí bí wọn ṣe ni fi òfin dè awọn oloṣèlú ní Burkina Faso, lẹ́yìn àwọn ìgbésẹ̀ tuntun tí ìjọba ológun ṣe láti fa àkókò iṣejọba rẹ̀ gùn àti láti fòfin de àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú.
Ní nǹkan bí ọdún mẹ́rin…
Ẹgbẹ Òṣelu APGA Fọwọsi Gbigbé Òfin Ìdìbò Kalẹ̀
Ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Grand Alliance (APGA) ti gbà ìgbékalẹ̀ Òfin Ìdìbò tuntun orílẹ̀-èdè yii, wọ́n yin Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu fún fífọwọ́ sí òfin náà ni kíákíá, wọ́n sì ṣàpèjúwe rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìgbésẹ̀ sí fífún àwọn ìlànà…
Ẹgbẹ́ Òṣèlú APGA Fọwọ́sí Gbigbé Òfin Ìdìbò Kalẹ̀
Ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Grand Alliance (APGA) ti gbà ìgbékalẹ̀ Òfin Ìdìbò tuntun orílẹ̀-èdè yii, wọ́n yin Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu fún fífọwọ́ sí òfin náà ni kíákíá, wọ́n sì ṣàpèjúwe rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìgbésẹ̀ sí fífún àwọn ìlànà…
Ilé iṣẹ́ Ààrẹ ṣàlàyé ìpàdé Tinubu pẹ̀lú àwọn afaragbà ní pápákọ̀ òfurufú
Ilé iṣẹ́ Ààrẹ ti ṣàlàyé ìdí tí Ààrẹ Bọla Tinubu fi bá àwọn afaragbà ìkọlù tó ṣelẹ̀ láìpẹ́ yìí ṣèpàdé ní Plateau, ní pápákọ̀ òfurufú Yakubu Gowon dípò ṣíṣe àbẹ̀wò sí àwọn agbègbè tí ìkọlù náà ti…
Àjíǹde : Arábìnrin àkọ́kọ́ pè fún ìfẹ́, àtẹ̀mọ́ra láàrin àwọn ọmọ Nàìjíríà
Arábìnrin Àkọ́kọ́ Nàìjíríà, Olurẹmi Tinubu, ti rọ àwọn ọmọ lẹ́yìn Kírísítì ní orílẹ̀-èdè láti ṣàfihàn ìfẹ́ sí àwọn alábágbé wọn, pàápàá jùlọ àwọn aláìní. Ó pe ìpè yìí nínú ọ̀rọ̀ ìfiránṣẹ́ rẹ̀ sí…
Ààrẹ Tinuba, Adarí Chad ṣe àtúnyẹ̀wò lórí àjọṣepọ̀ ààbò
Ààrẹ Bọla Tinibu ti pinnu láti ṣàtúnyẹ̀wò lórí ìfọ̀rọ̀jomi toro ọ̀rọ̀ pẹ̀lú Chad láti kojú jàgídíjàgan àti adigunjalè ní Ẹkùn Lake Chad, tí ó sì ń fi ìdí ìpinnu Nàìjíríà múlẹ̀ láti ṣèmúdúró àjọṣepọ̀…