Browsing Category
Ó GBÓNÁ FẸLI-FẸLI
This is a category for LATEST NEWS
NMA banújẹ́ Lórí Ètò Ìtọ́jú Ìlera Alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ tó mẹ́hẹ
Ẹgbẹ́ Ìṣòògùn Nàìjíríà (NMA),ti banújẹ́ lórí Ètò Ìtọ́jú Ìlera Alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ tó mẹ́hẹ ní Nàìjíríà,ó sọ pé ó léwu fún ìlera ọmọnìyàn.
Aarẹ ẹgbẹ naa, Dokita Innocent Ujah, sọ ni Port Harcourt, Ipinlẹ…
Gómìnà ìpínlẹ̀ Kano tẹ́lẹ̀ rí, Shekaráú, Fi APC sílẹ̀, Ó Darapọ̀ mọ́ NNPP
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kano tẹ́lẹ̀ rí, Sẹ́nétọ̀ Ibrahim Shekarau, ti fi ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress, APC sílẹ̀,tí ó sì dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú New Nigeria Peoples Party, NNPP.
Oludari Agba fun ẹgbẹ to n ṣatilẹyin fun Asiwaju Bọla…
Big Brother Nàìjá ẹlẹ́ẹ̀keje bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹu
Big Brother Nàìjá ẹlẹ́ẹ̀keje bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹu.
Awọn oluṣeto idije naa,fihan ninu fidio gigun iṣẹju kan ti o pin lori awọn ibaraẹnisọrọ lori ayelujara rẹ,o kede pe iṣafihan ọfẹ yoo nilo, ki awọn olukopa ṣafihan fidio iṣẹju mẹta lori…
Gómìnà Tambuwal dín ìséde oní Wákàtí mẹ́rìnlé-lógún kù Ní Ìpínlẹ̀ Sókótó
Ní Àtẹ̀lé ìfitónilétí kan nípasẹ̀ Àwọn olórí Ààbò ní Ìpínlẹ̀ Sókóto,́ Gómìnà Àmínù Wàzírì Tambuwal, ti pàṣẹ láti dín ìséde oní wákàtí -lógún ọ̀hún kù ní Ìpínlẹ̀ náà.
Ilana isede ti wọn tun…
Àwọn iṣẹ́ àkànṣe:Ẹ dá ṣẹ̀ríà fún àwọn olùgbaṣẹ́ṣe tí kò dúró déédé
Ìgbìmọ̀ tó ń mójútó owó ìfúnni ní àwọn ilé-ẹ̀kọ́ gíga (TETFund) ní Nàìjíríà, sọ pé ó ti fún àwọn ilé-ẹ̀kọ́ gíga tí ó ń jàǹfàní láti inú àwọn ìṣedúró rẹ̀ láṣẹ láti fòpin sí iṣẹ́ náà àti àwọn…
Ọ̀ṣun 2022: Ọ̀gọ̀ọ́rọ́ Àwọn Olólùfẹ́ PDP ń Yípadà sí APC Ní ìjọba ìbílẹ̀ Ayédáadé
Ipò ẹgbẹ́ òṣèlú alátakò pàtàkì nípínlẹ̀ Ọ̀sun, People’s Democratic Party, PDP, ti dín kù gan-an nígbà tí ó lé ní ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta lára àwọn ọmọ ẹgbẹ́ rẹ̀ ló ti kéde pé àwọn fẹ́ dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressive Congress, APC, ní…
Málì yọwọ́ kúrò ní ìgbógun ti ẹkùn Jihadist
Ilé-ìgbìmọ̀ ìjọba Málì sọ pé òun yóò jáwọ́ lórí ipa gbígbógun ti jihadist Iwọ̀-oòrùn Áfíríkà, lẹ́yìn tí ó ti dínà mọ láti gba ipò Ààrẹ ẹgbẹ́ agbègbè náà.
Bi orilẹ-ede naa ṣe kuro labẹ aabo G5 Sahel ni…
Orílè-èdè Sòmálíà Tún dìbò yan Ààrẹ Sheikh Mohamud
Orílè-èdè Sòmálíà dìbò yan Hassan Sheikh Mohamud sí ipò Ààrẹ fún ìgbà kejì lẹ́yìn ìdìbò ọlọ́jọ́ pípẹ́ ní ọjọ́ àìkú, ní orílẹ̀-èdè Iwọ̀ Áfíríkà tí ó wà ní hílàhílo, tí ó ń dojúkọ ìṣọ̀tẹ̀ àwọn…
Aṣojú ẹgbẹ́ APC ní ìpínlẹ̀ Kàdúná àti Niger Fòhùntẹ̀ lu Tinúubú
Àwọn aṣojú ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress ní ìpínlẹ̀ Kàdúná àti Niger ti fọwọ́sí èròńgbà fún ipò ààrẹ olóyè ẹgbẹ́, Asiwájú Bọ́lá Tinúubú.
Gẹgẹ bi atẹjade ti ile- iṣẹ ibaraẹnisọrọọ Tinubu gbe jade, awon…
NGO ṣe ìfilọ́lẹ̀ Ilé-akéde fún oko dídá ní Nàìjíríà
Láti ṣe àlékún ìṣelọ́pọ̀ àgbẹ̀ ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Ẹgbẹ́ tí kìí ṣe tìjọba (NGO), ti ṣe ìfilọ́lẹ̀ ilé-akéde asọ̀rọ̀mágbèsì fún iṣẹ́ ọ̀gbìn láti dé ọ̀dọ̀ àwọn àgbẹ̀ ní àwọn agbègbè ìgbèríko lórí…