Take a fresh look at your lifestyle.
Browsing Category

ÌRÒYÌN ÀṢÀ ÀTI ÌṢE YORÙBÁ

This is a category for culture and life news

Asiwaju Bola Ahmed Tinubu fi Aláàfin Ọ̀yọ́ tó wàjà, Ọba Lamidi Adeyemi III wé “ọpọ́n…

Asiwaju Bola Tinubu ló sọ ọ̀rọ̀ yí di mímọ̀ ní àsìkò tí wọ́n ṣe ádùrá ọjọ́ kẹjọ ní ìrántí ìpapòdà Aláàfin Ọ̀yọ́, Ọba Lamidi Adeyemi III. Ètò ọ̀hún ló wáyé ní Aganju tó wà ní Ààfin ìlú Ọ̀yọ́, ní ìpínlè Ọ̀yọ́ tó wà ní ẹkùn gúsù Iwọ̀ oòrùn…

Gómìná Ṣèyí Mákindé Kẹ́dùn Ikú Aláàfin Ọ̀yọ́, Ọba Làmídì Adéyẹmí III

Gómìná Mákindé, ẹni tí ó fi ìkíni ẹkú ará fẹ́rakù ránṣé sí ìgbìmọ̀ Ọ̀yọ́mèsì, ìdílée Ọba Làmídì Adéyẹmí III, àwọn ọmọ bíbí ìlú Ọ̀yọ́ àti gbogbo ọmọ Ilẹ̀ káàrọ́-ọ̀ jíire nígbàtí ó gbà ládùráà kí…

Àdánù ńlá ló sẹ lẹ̀ ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́: Ọmọọba Akeem Adeyẹmi

Ọmọọba Akeem Adéyẹmí tó s'ojú ẹkùn Ọ̀yọ́ ní Ilé ìgbìmọ̀ asòfin orílẹ̀ èdè Nàìjírìa ló so òrò yí di mímọ̀ ní Ààfin ní ìlú Ọ̀yọ́, ní ẹkùn gúsù Ìwọ òòrùn orílẹ̀ èdè Nàìjírìa nígbàtí ó sàlàyé…

Mi ò ní yí padà kúrò lórí ìlànà bí wọ́n ṣe ń jẹ olúbàdàn -Ṣèyí Mákindé

Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Ṣèyí Mákindé ṣe àbẹ̀wò ẹkú araá-fẹ́ra kù sí opó Ọba Sálíù Adétúnjí, Ajéogungun I, Olúbádàn ti ìlú Ìbàdàn tí ó sì fi àsìkò ọ̀hún sèlérí pé ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ yóò ṣe ayẹyẹ…
button