Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌDÓKOÒWÒ
This is a category for business news
NIDOE yóò Dá ibùjókòó ìdókòwò fún àwọn ọmọ Nàìjíríà tí wọ́n ń gbé ní òkè…
Ẹgbẹ́ Àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tó ń gbé lókè òkun (NIDOE), ẹ̀ka orílẹ̀-èdè Itali , sọ pé ó ń gbèrò láti kọ́ ọ̀pọ̀lọpọ̀ mílíónù dọ́là 'Diaspora Village' ní Nàìjíríà gẹ́gẹ́ ,bí ara àwọn…
Ìjọba Nàìjíríà Pín Owó tó tó Ọgọrun Bilionu Naira Fún Ìdásílẹ̀ Isẹ́
Ìjọba Nàìjíríà ti kéde pé òun ti pín ọgọ́rùn-ún bílíọ̀nù náírà láti fi dá iṣẹ́ sílẹ̀ fún àwọn ọ̀dọ́ àti láti kojú àìríṣẹ́ṣe tó ń gbòòrò sí i ní Nàìjíríà.
Eyi jade ninu atejade kan lati ọwọ Minisita fun iṣẹ, Ọgbẹni Festus Keyamo, SAN,…
Ààrẹ Buhari fi Nàíjíríà sílẹ̀ lọ sí Turkey
Aarẹ orilẹ ede Naijria, Muhammadu Buhari ti fori le Istanbul, to wa ni Turkey, lati lọ fun ipade apero ẹlẹkẹẹta ti yoo waye laarin Turkey ati orilẹ ede Afirika.
Aarẹ Buhari ni yoo wa nibi ipade apero ti yoo maa waye laarin…
orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti ṣí ìpàtẹ ọjà elẹ́ẹ̀kẹrin fún àwọn okòòwò abẹ́lé
Nàìjŕíà ti ṣíí ìpàtẹ ọjà ẹlẹ́ẹ̀kẹrin fún àwọn olókòòwò alábọ́ọ́dé ,MSMEs, ní Ìpínlẹ̀ Imo.
Ṣiṣii ohun elo ti a pin, eyiti o jẹ aaye nibiti ijọba pese ọpọlọpọ awọn ohun elo ati awọn ẹrọ fun oniruuru karakata…
A ń Sisẹ́ Pẹ̀lú Ìlànà Ẹrọ Dígítà Títí Ọdún 2025
Aláṣẹ àwọn ibùdó ọkọ̀ ojú omi Nàìjíríà (NPA) ti ṣàlàyé ṕe ètò ti wà ní pẹsẹ́ láti ri wí pé ẹ̀ka ibùdó ọkọ̀ ọjú omi Nàìjíríà sisẹ́ pẹ̀lú ìlànà imọ ẹrọ ayelujara, iyẹn dígítà tí yóò bá fi da ọdún 2025…
Ààrẹ Buhari Balẹ̀ Sí Ìlú Dubai
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti balẹ̀ sí Dubai, United Arab Emirates láti kópa nínú àpérò EXPO 2020.
Ààrẹ dé ìlú Dubai ní òwúrọ̀ ọjọ́ Ojóbò; asojú Nàìjíríà sí UAE, Mohammed Rimi àti Ambassador UAE sí Nigeria, Dr Fahad…
Ààrẹ Buhari Jíròrò Pẹ̀lu Àwọn Olùdókòwo
Nínú ìjíròrò pẹ̀lú àwọn olùdókòwò, Ààrẹ Buhari fi dá wọn lójú pé, ìdókòwò lórí gaasi ló jẹ Nàìjíríà lógún jù, nítorí àwọn àǹfààní tó rọ̀ mọ.
Nigbati o n ba alakoso Total, Patrick Pouyanne sọrọ;…
Ètò Ọrọ̀-Ajé Nàijìríà Dára
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàijìríà, Muhammadu Buhari sọ pé ètò ọrọ̀-ajé Nàijìríà wà ní pípé, ó sì dáńtọ́.
Aarẹ tẹsiwaju, o sọ pe, awọn ohun ameyedẹrun to le ṣe ọrọ-aje Naijiria láǹfààní ti wa nilẹ; ni eyi ti yoo jẹ…
Kò Séwu Lóko Alóńgẹ ẹ̀rọ alátagbà Netwọọki 5G
Àjọ tó ń bójútó ẹ̀rọ ìbáraẹnisọ̀rọ̀ lorilẹ ede Naijiria (NCC) ti fi dá àwọn ọmọ Nàíjírià lójú pé ẹrọ alatagba netwọọki 5G kò béwudé rárá.
Igbakeji alaga fun igbimọ naa, Ọjọgbọn Umar Danbatta lo sọ eyi ni ọjọ Aje.…
Nàìjíríà nílò ọ̀kẹ́ àìmọye dọ́là fún ìdàgbàsókè amáyédẹrùn
Ààrẹ Muhammadu Buhari,ti ni orílẹ̀ èdè Nàìjíríà yóò nílò ọ̀kẹ́ àìmọye owó ilẹ̀ òkèèrè tó lé ni tiriọnu dọla fún ètò ìdàgbàsókè ohun amáyédẹruǹ.
Ààrẹ Muhammadu Buhari sọrọ yii lọ́jọ́ Ìsẹ́gun níbi…