Nínú ìjíròrò pẹ̀lú àwọn olùdókòwò, Ààrẹ Buhari fi dá wọn lójú pé, ìdókòwò lórí gaasi ló jẹ Nàìjíríà lógún jù, nítorí àwọn àǹfààní tó rọ̀ mọ.
Nigbati o n ba alakoso Total, Patrick Pouyanne sọrọ; Aarẹ ṣe akiyesi pe Naijiria ti ṣe awọn idoko-owo to jọju lori gaasi, ati pe wọn o ni sinmi lati maa ṣe eyi, ki wọn le dekun awon eefi to le ṣe eniyan ni jamba.
Leave a Reply