Browsing Category
ÌRÒYÌN ILẸ̀ ÀFÍRÍKÀ
This is a category for Africa news
Kò sí Ìfọ̀kànbalẹ̀ Ní Zamzam, Orílẹ̀-èdè Sudan Látàrí Rúkè-rúdò Tí Ó Ń Wáyé-…
Agbẹnusọ akọ̀wé àpapọ̀ àjọ àgbáyé ti sàlàyé pé rúkè-rúdò tí ó ń wáyé ní Orílẹ̀-èdè Sudan ti fa ìdààmú dààbo, àìfàyàbalẹ̀ ọkàn, tí ó sì mú kí ìgbé ayé le koko ní àgbègbè náà
…
Ìyàwó Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ṣé Ìlérí Àtìlẹ́yìn Fún Àwọn Obìnrin Àti Ọdọ
Àyá Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Oluremi Tinubu sọ pé òún tí pinnu látí ṣé ìpolongo, koriya àti ìdásílẹ̀ àwọn àjọṣepọ̀ tí yóò fún àwọn obìnrin àti àwọn ọdọ Nàìjíríà ní àgbàrá láti ṣiṣẹ́.
O n sọrọ yíi l'àkókò Àpéjọ Gbogbogbò tí…
Nàìjíríà Àti AU T’ọwọ́ Bọ́ Ìwé Àdéhùn Ààbò Lórí Àwọn Òkun
Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí f'ọwọ́ sí ìwé àdéhùn kán pẹ̀lú Ẹgbẹ́ Áfíríkà láti pèsè àwọn iṣẹ́ Ìgbésókè Òkun láti ṣé àtìlẹ́yìn àláfíà fún ẹgbẹ́ AU, àtìlẹ́yìn àjálù àdáyébá, ìdáàbòbò ọmọnìyàn àti àwọn ìrìn àjò wọ́n.
Mínísítà fún ààbò…
Rògbòdìyàn Sudan: Ọ̀gá Àjọ UN Pè Fún Ìrànwọ́ Àgbáyé
Akọ̀wé àgbà àjọ ìsọ̀kan àgbáyé UN General António Guterres níbi Ìpàdé àgbáríjọpọ̀ ilẹ̀ Adúláwọ̀ ni Addis Ababa, ti pe àjọ àgbáyé láti dìde ni kíámọ́sá fún ìrànlọ́wọ́ orílẹ̀-èdè Sudan níbi tí rògbòdìyàn ti ń selẹ̀.
Níbi tó ti…
Ààrẹ Tinubu Gúnlẹ̀ Sí Orílẹ̀-èdè Ethiopia Fún Àpérò Ilẹ̀ Adúláwọ̀
Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Bọla Ahmed Tinubu ti gúnlẹ̀ sí ìlú Addis Ababa, Ethiopia ní alẹ́ Ọjọ́bọ̀ láti kópa nínú ìpàdé àpérò ilẹ̀ adúláwọ̀ ẹlẹ́ẹ̀kejìdínlógójì irú rẹ̀ pẹ̀lú àwọn akẹgbẹ́ rẹ èyí ti yóò…
Àwọn Aṣojú Ìjọba Ilẹ̀ Áfíríkà Kẹ́dùn Olóògbé Nujoma Pẹ̀lú Nàmíbíà
Ìgbìmọ̀ Àwọn aṣojú orílẹ̀-èdè Áfíríkà tí darapọ̀ mọ́ àwọn yòókù lágbayé láti ṣọfọ ikú Sam Nujoma, Ààrẹ àkọkọ́ ní Orílẹ̀-èdè Namibia lẹyìn òmìnira, tó kú ní ẹní odún márún dín lọgọ́rùn (95).
Nujoma jẹ́ olókìkí ajá-fẹtọ́-ọmọnìyàn,…
Orílẹ̀-èdè Libya Rí Òkú Àwọn Arìnrìnàjò Ní Ibojì Ọ̀lọ́pọ̀ Ènìyàn
Ìjọba Orílẹ̀-èdè Libya ti rí òkú àwọn arìnrìnàjò Àádọ̀ta ni ọ̀sẹ̀ yìí nínú ibojì méjì ọ̀lọ́pọ̀ èniyàn ni aginjù aṣálẹ̀ gúsù ìlà oòrùn orílẹ̀-èdè bi àwọn òṣìṣẹ́ se sọ.
Ọ̀kàndínlógún òkú ni wọ́n rí ní ọjọ́ Ẹtì ní oko kan ni ìlú…
Áfíríkà Kí Ifè Ẹ̀yẹ Àgbáyé Káàbọ̀
Bó tí kú oṣù díẹ̀ tí ìdíje àgbáyé àwọn ẹgbẹ́ àgbábọ́ọ̀lù yóò fí wáyé ní orílẹ̀-ẹ̀dẹ̀ Amẹ́ríkà, Áfíríkà gbàlejò ifè túntún náà.
Ẹgbẹ́ agbabọọlu méjìlélọ́gbọ̀n 32 ní yóó kópa nínú ìdíje túntún náà níbí tí ẹgbẹ́ àgbábọ́ọ̀lù mẹ́rin yóò tí…
Bísọ́ọ̀bù Àgbà Orílẹ̀-èdè South Africa Tọrọ Àforíjì Látàrí Ẹ̀sùn Ìlòkulò Ọmọdé
Bísọ́ọ̀bù àgbà ti ìlú Cape Town se ìpàdé ní ọjọ́ ìṣẹ́gun lẹ́yìn àgbéyẹ̀wò tí wọ́n rí pé àwọn ìgbìmọ̀ mọ̀ pé ìjọ Anglican ni South Africa kùnà láti sọ fún àwọn ìjọ míràn ewu tó lágbára tó wà níbẹ látàrí ìlòkulò ọmọdé lọ́wọ́…
Àwọn alájọṣepọ̀ ààrẹ Benin fi ẹ̀wọ̀n ogún ọdún gbára lórí ìgbèrò ìfipá gbàjọba
Àwọn arákùnrin méjì kan tí wọ́n súnmọ́ ààrẹ orílẹ̀ - èdè Benin, ti fi ẹ̀wọ̀n ogún ọdún gbára lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n mú wọn lọ́dún tó kọjá lórí ìgbèrò ìfipá gbàjọba lórílẹ̀ èdè náà.
Ile Ẹjọ ti n risi ẹṣẹ…