Take a fresh look at your lifestyle.
Browsing Category

ÌRÒYÌN ÀṢÀ ÀTI ÌṢE YORÙBÁ

This is a category for culture and life news

Mínísítà Nipa Iṣẹ́ Ọnà Ṣèlérí Àjọṣepọ̀ Pẹ̀lú Mínísítà Àná, Ade-John Fún Ìgbéga Ètò Ìrìnàjò Àti…

Mínísítà iṣẹ́ ọnà, àṣà àti ìrìnrìnàjò àti ọgbọ́n àtinúdá ọ̀rọ̀ aje, Hannatu Musawa ti sọ pé òún yóò gba ìmòràn ati iriri ẹni iṣaju òun, Lola Ade-John lò fún ìtèsíwájú ẹ̀ka náà. Níbi ayẹyẹ ìfisẹ́léniilọ́wọ́ ni Ọ́fíìsì rẹ̀ ni…

Ààrẹ Tinúbú Gbóríyìn Fún Ọọ̀ni Ilé Ifẹ̀ Fún Gbígbé Àṣà Àti Ìse Ilẹ̀ Yorùbá Lárugẹ

Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Bọ́lá Ahmed Tinubú ti gbósùbà ràbàndẹ̀ fún Ọọ̀ni ti ilé-ifẹ̀ (Oba Adeyeye Ogunwusi) látàrí bí ó se ń gbé àṣà àti ìṣe ilẹ̀ Yorùbá lárugẹ. Ààrẹ Tinubu wí pé, láti ìgbà Kábíyèsí ti gorí ìtẹ́ baba rẹ̀, ìṣàkóso rẹ̀…

Arólé Oòduà Ọba Adeyeye Ojaja II Ṣé Ìfilọ́lẹ̀ Ẹ̀sìn Adúláwọ̀ Ní Orílẹ̀-èdè Brazil

Ẹní ọ̀wọ̀ àtí alága àwọn Ọba lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà (National Traditional Council), Ọọ̀ni tí ilé Ifẹ, H.I.M Adeyeye Enitan Ogunwusi, Ọjaja II, tí ṣé ìfilọ́lẹ̀ ọjọ́ ẹsìn ìbílẹ̀ adúláwọ̀ tí ọdọọdún tí á pé àkọlé rẹ̀ ní "Ọjọ́ Ìṣẹ̀ṣé," ní…

Ọba Sulu-Gambari Gbóríyìn Fún Ìjọba Àpapọ̀ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Fún Ìdásílẹ̀ Ìgbìmọ̀ Aláṣẹ Ẹ̀kọ́…

Emir tí Ìlú Ilorin àti Alága Ìgbìmọ̀ Ọba àti Oyè Ìbílẹ̀ tí Ìpínlẹ̀ Kwara, Alhaji Ibrahim Sulu-Gambari tí gbóríyìn fún Ìjọba Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà fún ìdásílẹ̀ Ìgbìmọ̀ aláṣẹ ètò Ẹ̀kọ́ Ilé-ìwé gírámà tí Orílẹ̀-èdè yìí, (National Secondary…

Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Yóò Sì ilẹ́ ẹ̀kọ́ Ohun Ìṣẹ̀nbáyé.

Mínísítà fún ìròyìn, Àṣà,ati Ìṣẹ ni orílẹ̀-èdè Nàìjíríà,ń ṣiṣe lọ́wọ́lọ́wọ́ pẹ̀lú UNWTO, àwọn tọrọ kan, àti àwọn ilé iṣé aláàdáni láti rí wí pé wọ́n dá ilẹ́ ẹ̀kọ́ isẹ̀báyè sílẹ̀ ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Alhaji Lai mohammed ti o…
button