Browsing Category
ÌRÒYÌN ÀṢÀ ÀTI ÌṢE YORÙBÁ
This is a category for culture and life news
Oloro Ti Oro Tuntun Gorí Ìtẹ́ Lẹ́yìn Ẹ̀tàlélógòjìlénígba Ọdún Tí Ìran wọn Ti Jẹ
Ọjó málegbàgbé àti ọjọ́ ayọ̀ ló jẹ́ ni ilú Oro nígbà ti Oba alayeluwa tuntun, Joel Olaniyi Oyatoye Titiloye Olufayo II gorí ìtẹ́ àwọn bàbá rẹ pẹlú adé lori.
Èyí wáyé lẹ́yìn Ẹ̀tàlélógòjìlénígba Ọdún ti Iran wọn ti je gbẹ̀yìn.…
Mínísítà Nipa Iṣẹ́ Ọnà Ṣèlérí Àjọṣepọ̀ Pẹ̀lú Mínísítà Àná, Ade-John Fún Ìgbéga Ètò Ìrìnàjò Àti…
Mínísítà iṣẹ́ ọnà, àṣà àti ìrìnrìnàjò àti ọgbọ́n àtinúdá ọ̀rọ̀ aje, Hannatu Musawa ti sọ pé òún yóò gba ìmòràn ati iriri ẹni iṣaju òun, Lola Ade-John lò fún ìtèsíwájú ẹ̀ka náà.
Níbi ayẹyẹ ìfisẹ́léniilọ́wọ́ ni Ọ́fíìsì rẹ̀ ni…
Ìpínlẹ̀ Èkó Se Ìfilọ́lẹ̀ – Cultural Mission Movement
Olùdámọ̀ràn pàtàkì fún Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó lori ọ̀rọ̀ nipa arìnrìnajò,iṣẹ ọnà ati ,aṣa, ògbéni Idris Aregbe ti tẹnumọ ojúṣe ijoba ipinle Eko lati gbe asa ipinle naa laruge.
Ọgbẹni Aregbe so eyi nibi Ifilọ́lẹ àjọ Lagos Cultural…
Mínísítà Rọ Àwọn Amúlùúdùn Láti Gbé Àṣà Wa Lárugẹ.
Mínísítà fún àṣà, àti ìṣe wà, Amòfin Hannatu Musa Musawa tí gbà àwọn Amúlùúdùn Làmọ̀ràn láti túnbò teramọ́ ìdàgbàsókè Àṣà àti ìṣe wà ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Nínú ọ̀rọ̀ ìkíni ayẹyẹ a ku ẹwu ọdún ni ọ̀rọ̀ náà tí jáde.
Mínísítà ni òun fi…
Iwobi Rawọ́ Ẹ̀bẹ̀ Sí Àwọn Ọmọ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Láti Ní Sùúrù.
Ọmọ ẹgbẹ́ agbaboolu Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Alex Iwobi ti rawọ ẹ̀bẹ̀ sí àwọn olólùfẹ̀ rẹ láti ní sùúrù to pọ fún àwọn,
wọn ní àwọn yóò sa gbogbo agbara awọn láti rí wí pé àwọn kópa nínú ìdílé bọọlu àgbáyé ti ọdún 2026.
Orílẹ̀-èdè…
Ààrẹ Tinúbú Gbóríyìn Fún Ọọ̀ni Ilé Ifẹ̀ Fún Gbígbé Àṣà Àti Ìse Ilẹ̀ Yorùbá Lárugẹ
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Bọ́lá Ahmed Tinubú ti gbósùbà ràbàndẹ̀ fún Ọọ̀ni ti ilé-ifẹ̀ (Oba Adeyeye Ogunwusi) látàrí bí ó se ń gbé àṣà àti ìṣe ilẹ̀ Yorùbá lárugẹ.
Ààrẹ Tinubu wí pé, láti ìgbà Kábíyèsí ti gorí ìtẹ́ baba rẹ̀, ìṣàkóso rẹ̀…
Arólé Oòduà Ọba Adeyeye Ojaja II Ṣé Ìfilọ́lẹ̀ Ẹ̀sìn Adúláwọ̀ Ní Orílẹ̀-èdè Brazil
Ẹní ọ̀wọ̀ àtí alága àwọn Ọba lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà (National Traditional Council), Ọọ̀ni tí ilé Ifẹ, H.I.M Adeyeye Enitan Ogunwusi, Ọjaja II, tí ṣé ìfilọ́lẹ̀ ọjọ́ ẹsìn ìbílẹ̀ adúláwọ̀ tí ọdọọdún tí á pé àkọlé rẹ̀ ní "Ọjọ́ Ìṣẹ̀ṣé," ní…
Ọba Sulu-Gambari Gbóríyìn Fún Ìjọba Àpapọ̀ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Fún Ìdásílẹ̀ Ìgbìmọ̀ Aláṣẹ Ẹ̀kọ́…
Emir tí Ìlú Ilorin àti Alága Ìgbìmọ̀ Ọba àti Oyè Ìbílẹ̀ tí Ìpínlẹ̀ Kwara, Alhaji Ibrahim Sulu-Gambari tí gbóríyìn fún Ìjọba Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà fún ìdásílẹ̀ Ìgbìmọ̀ aláṣẹ ètò Ẹ̀kọ́ Ilé-ìwé gírámà tí Orílẹ̀-èdè yìí, (National Secondary…
Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Yóò Sì ilẹ́ ẹ̀kọ́ Ohun Ìṣẹ̀nbáyé.
Mínísítà fún ìròyìn, Àṣà,ati Ìṣẹ ni orílẹ̀-èdè Nàìjíríà,ń ṣiṣe lọ́wọ́lọ́wọ́ pẹ̀lú UNWTO, àwọn tọrọ kan, àti àwọn ilé iṣé aláàdáni láti rí wí pé wọ́n dá ilẹ́ ẹ̀kọ́ isẹ̀báyè sílẹ̀ ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Alhaji Lai mohammed ti o…
Ona TI Abaji,Alhaji Adamu Baba Yunusa sayẹyẹ ọdún márùndínlọ́gbọ̀n lórí ìtẹ́,ẹgbẹ́ ọmọ…
Ona of Abaji , to tun jẹ alaga igbimọ awọn lọba-lọba niluu Abuj,FCT ,His Royal Majesty (HRM) Alhaji Adamu Baba Yunusa sayẹyẹ sayẹyẹ ọdún márùndínlọ́gbọ̀n (25 years)lórí ìtẹ́, ni eyi ti gbogbo toni;e talejo wa sibi ayẹyẹ naa to waye…