Take a fresh look at your lifestyle.
Browsing Category

ÌRÒYÌN ÌDÓKOÒWÒ

This is a category for business news

Ìgbésẹ̀ Ààrẹ Tinubu Lórí Ètò Ọrọ̀ Ajé Yóò So Eso Rere Fún Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà-…

Gómìnà Ìpínlẹ Enugu, Peter Mbah ti sàpèjúwe ìgbésẹ̀ Ààrẹ Tinubu lórí ètò ọrọ̀ ajé gẹ́gẹ́ bí èyí tí ó tọ́, tí yóò sì so èso rere fún Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà   Mbah tẹ̀síwájú pé ìgbésẹ̀ láti ní…

Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Tún Yan Mele Kyari Gẹ́gẹ́ Bi Ọ̀gá Àgbà Pátápátá Fún Ilé iṣé NNPCL.

Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Bola Tinubu ti Yan Mele Kyari ni ìgbà Kejì gẹ́gẹ́ bí ọ̀gá àgbà pátápátá fún ilé iṣé tó ń mójú tó ọ̀rọ̀ Epo rọ̀bì ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà NNPCL. Ààrẹ tún buwọ́lù àwọn alábàáni ṣiṣẹ́ pọ̀ fún ilé iṣé náà Ààrẹ Yan…

COEASU gbóríyìn fún ààrẹ Tinubu fún ìdádúró ìdá ogójì nínú ọgọ́rùn ún

Ẹgbẹ́ àwọn olùkọ́ni ti ilé-ìwé olùkọ́ni, COEASU, ti gbóríyìn fún ààrẹ, Bọla Ahmed Tinubu fún bí ó ṣe lo ọgbọ́n tí ó sì dá ìlànà tí ó ní kí àwọn ilé ẹ̀kọ́ gíga lórílẹ̀-èdè máa san ìdá ogójì nínú ìdá…

Àwọn Ọmọ Orílẹ̀-ede Nàìjíríà Ti Gbáradì Láti Gbàlejò Olùdókoòwò Ilẹ̀ Òkèèrè-…

Ààrẹ Oriĺẹ̀-èdè Nàìjíríà Bọla Ahmed Tinubu ti sàpèjúwe àwọn Ọmọ Orí́lẹ̀-èdè Nàìjíríà gẹ́gẹ́ bí ọ̀jọ̀gbọ́n, ọlọ́pọlọ pípé, olùfarajì tí ó le è figa-gbága pẹ̀lú ojúgbà rẹ̀ ní àgbáyé Ààrẹ fi…

Ìpàdé Ìdókó-òwò Abẹ́lé Àwọn Ọmọ Nàìjíríà Lókè Okùn Ẹ̀kẹfà: Ọjọ́ Àkọ́kọ́

Níbí ìṣidé ìpàdé àwọn ọmọ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tó wà lókè okùn ẹlẹ́ẹ̀kẹfà irú rẹ̀ '6th Nigeria Diaspora Investment Summit' tó bẹ̀rẹ̀ láti ọjọ́ kẹtala sí ọjọ́ kẹ́ẹdógún, Oṣù Kọkànlá, Ọdún 2023, ilé-iṣẹ́ tó ń rí sí ọ̀rọ̀ àwọn ọmọ Orílẹ̀-èdè…
button