Take a fresh look at your lifestyle.
Browsing Category

ÌRÒYÌN ÒSÈLÚ

This is a category for politics news

Ìdájọ́ Ilé Ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn: Àjọ Ọlọ́pàá Pèpè Fún Àlàáfíà Àti Ìfọ̀kànbalẹ̀ Ní…

Àjọ Ọlọ́pàá Ìpínlẹ̀ Nasarawa ti se ìkìlọ̀ fún àwọn alátìlẹyìn ẹgbẹ́ òsèlú láti jìnà sí ìwà tí ó le è da omi àlàáfíà ìlú rú síwájú ìdájọ́ Ilé Ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn tí yóò wáyé ní ìpínlẹ̀ náà…

Kòsí Nínú Èrò Ìjọba Àpapọ̀ Láti Sọ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Di Èyí Tí Yóò Máa Lo…

Ìjọba Àpapọ̀ ti rọ ọmọ Orílẹ̀-èdè Nàìjiríà láti jìnà sí ìròyìn kan tí ó ń fò káàkiri nípa pé Ààrẹ Bọla Tinubu ń gbèrò láti sọ Nàìjíríà di Orílẹ̀-èdè tí yóò máa lo ẹgbẹ́ òsèlú kan ṣoso nípa…

Èsì Ìdìbò Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kano: Moni Ìgbàgbọ́ Pé Ilé Ẹjọ́ Tó Gajù Lọ Yóò Ṣe Ìdájọ́ Òdodo –…

Ẹni tíì ṣe èèkàn nínú ẹgbẹ́ òṣèlú New Nigeria People's Party (NNPP), Olufemi Ajadi Oguntoyinbo ti fi ọwọ́ sọ̀yà pé ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ (Supreme Court) yóò ṣe ìdájọ òdodo lórí Gomina Ìpínlẹ̀ Kano, Abba Yusuf. Oguntoyinbo tó jẹ́ bàbá…

Àsọdùn ọ̀rọ̀ ni ohun tí àwọn ènìyàn ń sọ nípa iye owó tí ìjọba àpapọ̀ fẹ́ fi ra ọkọ̀…

Asofin to n soju fun ẹkun Irẹpọ,Orelope  ati Ọlọrunsogo ní ipinlẹ Ọyọ, ọmọọba Lateef Ọlaide Mohammed ti ni ko si otitọ nipa ọrọ ti awọn eniyan ń sọ nipa iye owó ti ijọba apapọ fẹ fi ra ọkọ ti awọn asofin fẹ fi maa ṣe isẹ wọn. wọn…
button