Browsing Category
KÓKÓ INÚ ÌRÒYÌN
This is a category for featured story
COAS Ṣé Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ Pẹ̀lú Àwọn Aṣíwájú Ní Ìpínlẹ̀ Niger Láti Dẹ́kun Ìpániláyà
Olórí Ẹgbẹ́ Àwọn Ọmọ-ogun ti mú ìsapá wọn pọ̀ sí i láti mú kí Ìpínlẹ̀ Niger dúró ṣinṣin nípa ṣíṣe ìfọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú àwọn Ọba àti àwọn olórí ìbílẹ̀ nínú àtúnyẹ̀wò gbígbòòrò kán lórí ìfiránṣẹ́ àwọn ológun, ìmúlò ìmọ̀ ẹ̀rọ, àti ìmúrasílẹ̀…
Ààrẹ Tinubu Kí Aremu Kú Oríire Ọjọ́ìbí
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu ti kí Comrade Issa Obalowu Aremu, Olùdarí Àgbà ti 'Michael Imoudu National Institute for Labour Studies (MINILS)', ní ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ọdún márùnlélọ́gọ́ta rẹ̀, ó sì yin iṣẹ́ ìsìn rẹ̀ fún ọ̀pọ̀ ọdún sí ìgbòkègbodò…
Olórí Ẹgbẹ́ Ọmọ-ogun Tún Jẹ́rìí sí Ààbò Àwọn Ọmọ-ogun
Olórí Ẹgbẹ́ Ọmọ-ogun, Lt. Gen. Waidi Shaibu, ti tún ṣé ìdánilójú pé ẹgbẹ́ ọmọ-ogun Nàìjíríà yóò máa ṣètìlẹ́yìn fún àwọn olórí àti àwọn ọmọ-ogun pẹ̀lú àwọn ètò ìlera tó yẹ, àwọn ohun èlò ìṣiṣẹ́ àti àtìlẹ́yìn àwọn olórí tó yẹ láti jẹ́ kí wọn…
Ìkọlù Àwọn Agbébọn Sí Ọfiisi Ọgbà Ìtọ́jú Ẹranko Àtijọ́: Makinde Ṣèlérí Òpin Sí Irú Ìkọlù Bẹẹ
Látàrí ìṣẹ̀lẹ̀ ìkọlù àwọn agbébọn sí àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ìtọ́jú ẹranko àtijọ ni Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí àwọn ènìyàn agbègbè náà láti ṣe sùúrù.
Ìṣẹ̀lẹ̀ ìkọlù àwọn agbébọn eléyìí ti Alukoro ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, DSP…
Sarkin Hausawa Ìlú Ìbàdàn Gbésẹ̀: Makinde Kẹ́dùn Pẹ̀lú Olúbàdàn Àti Ẹ̀yà Hausa Ní Ìlú Ìbàdàn
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti fi ikú Sarkin Hausawa ìlú Ìbàdàn, Alahji Ali Dahiru Zungeru we àdánù nla.
Gómìnà, ẹni tó fi olóògbé Zungeru wé olólùfẹ́ àlàáfíà àti adarí tó ṣeé gbẹ́kẹ̀lé náà ló bá Olúbàdàn ilẹ̀ Ìbàdàn,…
Ẹgbẹ́ ikọ̀ Agbábóòlù Chelsea Yan Liam Rosenoir Gẹ́gẹ́ Bí Olukọni Àgbà Fún Ẹgbẹ́ Náà
Ẹgbẹ́ Agbábóòlù Chelsea so wí pè Títí di ọdún 2032 ni Rosenior yóò fí wá ni ipo Olukọni àgbà, fun ẹgbẹ́ náà ọ̀rọ̀ yìí jade ní ọjọ́ ìṣẹgun.
Rosenior ló kó ikọ̀ Agbábóòlù Strasbourg ló ṣì Orílẹ̀-èdè European fún ìdíje ṣùgbọ́n ni báyìí o ti…
Ẹ jẹ́ kí Àlàáfíà Joba Lásìkò Ìdìbò Ọdún 2027: Gómìnà Ìpínlẹ̀ Akwa Ibom
Gómìnà ìpínlẹ̀ Akwa Ibom Olùṣọ Àgùntàn Uma Eno ti pe àwọn ará ìlú ati àwọn Olóṣèlú láti jẹ ki Àlàáfíà Joba Lásìkò Ìdìbò Odun 2027.
Gómìnà mu amoran àlàáfíà yìí wa lasiko ti wọn se idupe ọdun tuntun ni gbo gán International Worship ni…
Ẹgbẹ́ Ọmọ Ológun Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Tú Àṣírí Àwọn Oníṣẹ́ Láabi Ni Ìpínlẹ̀ Adamawa.
Ẹgbẹ́ Ọmọ Ológun Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti wọn n pé ni OPHK ti dènà ìwà ìbàjẹ́ ti yóò mú emi opolopo àwọn ènìyàn ló.
Ọwọ́ ba àwọn ènìyàn mẹjọ, ati àwọn odara meji miran ni inu ọjà Gamboru ni èyí tì wọn fẹ gbà Emi ara wọn ati àwọn ènìyàn…
Ẹgbẹ́ Ọmọ Ológun Orílẹ̀-èdè Ṣe Ìfilọ́lẹ̀ ìpàdé Fún Ìdanilẹ́ẹ̀kọ́ Odún 2026.
Ẹgbẹ́ Ọmọ Ológun Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti bẹ̀rẹ̀ ìpàdé fún Ìdanilẹ́ẹ̀kọ́ ti odún 2026 pẹ̀lú ètò ati ìlànà ẹ̀kọ́ ẹyi ti àjọ TRADOC ṣe agbáterù re.
Nígbà ti o n sọ̀rọ̀ níbi ayẹyẹ náà ọgá àgbà pátá fún ẹgbẹ́ Ọmọ Ológun Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà…
Ètò ìṣúná owó Ọdún 2026 Jẹ́ Àtìlẹ́yìn Nlá Fún Ààrẹ Tinubu: Mínísítà Fún Ọ̀rọ̀ Tó Ńlọ
Mínísítà fún ọ̀rọ̀ tó nlọ Alhaji Mohammed Idris so wí pè ẹ̀tọ̀ ìṣúná owó Ọdún 2026 jẹ ohun tí wọ́n fi ọgbọ́n àti làákàyè gbé kalẹ fún àtìlẹ́yìn ijoba Ààrẹ Tinubu.
Nínú ọ̀rọ̀ tó jáde láti ẹnu Mallam Rabiu Ibrahim to jẹ ìgbà Kejì pàtàkì…