Browsing Category
KÓKÓ INÚ ÌRÒYÌN
This is a category for featured story
Ìrìn Àjò Afẹ́: Makinde Ṣèlérí Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ Pẹ̀lú Oludókòwò
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti ṣèlérí pé ìṣèjọba òun ti ṣetán láti fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú àwọn Oludókòwò lójúnà àti mú ọrọ̀ ajé tó wà nínú ìrìn àjò afẹ́ ni Ìpínlẹ̀ náà jáde.
Makinde tún ṣèlérí wí pé òun yóò pèsè ìkúnlọ́wọ́ fún gbogbo…
Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ṣetán Fún Ìbáṣepọ̀ Tó Jinlẹ̀ Pẹ̀lú Orílẹ-èdè Tanzania.
Akọ̀wé àgbà fún ilé iṣé ìjọba fún ètò Ààbò, ọ̀mọ̀wé Ibrahim Abubakar Kana sọ wí pé Ìjọba Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ṣetán fún ìtèsíwájú ìbáṣepọ̀ tó dán móran pẹ̀lú Orílẹ̀-èdè Tanzania.
Ọ̀mọ̀wé Kana sọ èyí di mímọ nígbà tí ó gbàlejò láti…
Adari ilé ìgbìmọ̀ Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Anambra Ṣe Ìfilọ́lẹ̀ Gbingbin Ẹ̀gẹ́
Adarí ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ìpínlẹ̀ Anambra, Ọ̀gbẹ́ni Somtochukwu Udeze ti ṣe ìfilọ́lẹ̀ gbingbin ẹ̀gẹ́ ni ìjọba ìbílẹ̀ atani, Ogbaru ni ìpínlẹ̀ Anambra
Ó ni ìfilọ́lẹ̀ yìí yóò mú ìdàgbàsókè àti ìlọsíwájú bá ètò ọ̀gbìn fún àwọn agbègbè tó wa…
Òbí Tí A Bá Rí Ní Agbègbè Gbọgán Ìdánwò Yóò Ba Ará Rẹ Láàgọ́ Ọlọ́pàá.: Àjọ JAMB.
Àjọ tó n mójú tó ètò ìdánwò a ti wọlé sí ilé ẹ̀kọ́ gíga JAMB ti ṣe ìkìlọ tí o ni agbára wí pé àwọn òbí ti o ba yọjú sí àgbègbè ibi ìdánwò ki wọn mú gbà àgọ Ọlọ́pàá lo.
Ìdánwò náà yóò bẹ̀rẹ̀ ní ọjọ́ kọkànldinlogun oṣù kẹrin sí ọjọ́…
Ìgbìmọ̀ Ẹgbẹ́ Òṣèlú PDP Ṣe Ìlérí Láti Jẹ Agbára Fún Ẹgbẹ́ Náà.
Ìgbìmọ̀ Ẹgbẹ́ Òṣèlú PDP ti ṣe ìlérí láti ṣiṣẹ takuntakun fún igbedide àti òkun fún ẹgbẹ́ òṣèlú PDP.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Bauchi tó tún jẹ Alága fún ìgbìmọ̀ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP Bala Mohammed lo sọ èyí di mímọ nígbà tí o n ba àwọn oníròyìn sọrọ…
Igbákejì Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Dé Sí Ìpínlẹ̀ Jigawa.
Igbákejì Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Kasham Shettima bro kalẹ báyìí sí ìpínlẹ̀ Jigawa fún ibẹwo ọlọkàn.
Pápákọ̀ òfurufú Dutse ni wọn ti lo ṣe ìkíni káàbọ̀ igbákejì Ààrẹ ni dédé àgọ mẹwàá kọjá iṣẹju márùn owurọ̀.
Igbákejì Ààrẹ ni àlejò…
Ìdíje Tennis: Rafael Nadal Bẹ̀rẹ̀ Jíjáwé Olùborí Ni Ilu Barcelona
Ìràwọ̀ agbábọ́ọ̀lù Tennis, ọmọ orílẹ̀-èdè Spain, Rafael Nadal ti pada sinu ìdíje ni oṣù kínní odun ni Brisbane láti nǹkan bí ọdún kan latari ifarapa ibi ìdí to nilo iṣẹ abẹ. Ẹ̀wẹ̀, ifarapa ti fẹ hee leemọ̀, Ifarapa iṣan ese yiya…
Orílẹ̀-èdè Ivory Coast Se Àjoyọ̀ Ọjọ́ Àyájọ́ Agbègbè Ìlú Wọn
Ni ọdọọdún, ènìyàn ilu Abidjis ti won n gbe ni guusu ìlà oorun abule Yaobou a máa se ajoyọ idasile agbegbe wọn.
Ayẹyẹ náà ni won n pé ni ọdún 'dipri'
Ni ede ibilẹ̀, 'di' tumo sí omi àti pé 'pri' náà túmọ̀ sí ìgbéra pá. Àwọn…
Ayò Ẹlẹ́yin Lórí Tábìlì: Aruna Wà Ní Ipò Kọkàndínlógún Lágbáyé
Ogbontarigi agbábọ́ọ̀lù ẹlẹ́yin lórí tábìlì ọmọ Nàìjíríà, Quadri Aruna, ti wa ni ipo kọkàndínlógún lagbaye bayii lára àwọn to dara ju ninu àtẹ ìwọ̀n ITTF ti won ṣẹṣẹ gbe jade.
Aruna bẹrẹ ìdíje ITTF agbaye-Macao 2024 dáradára…
Arábìnrin Àkọ́kọ́ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ró Àwọn Àgbẹ̀ Obìnrin Lágbára.
Arábìnrin àkọ́kọ́ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Oluremi Tinubu ti síde ètò àtúnṣe ireti ọtun ní ẹka ti ọgbin fún agbegbe ìwọ̀ oòrùn Nàìjíríà
Ó sọ pé òun se èyí ní ọ̀nà láti mú ìlérí òun ṣẹ ni ọna lati máa gbe awọn obinrin ga jakejado…