Take a fresh look at your lifestyle.
Browsing Category

KÓKÓ INÚ ÌRÒYÌN

This is a category for featured story

Ètò Ìlera Ọ̀fẹ́: Makinde Ṣíde Ìfilọ́lẹ̀ Ìlera Ọ̀fẹ́ Ní Ìjọba Ìbílẹ̀ Àríwá/Ìlà-Oòrùn Ìbàdàn.

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti jẹ ko di mímọ̀ pé ìṣèjọba òun yóò tẹ síwájú láti máa pèsè ètò ìlera lójúnà àti ri dájú pé ará ìlú wa ni ìlera pípé eléyìí tí yóò mú kí ọrọ̀ ajé rú gọ́gọ́ síi, ti ìṣẹ yóò sì dínkù ni àwùjọ. Makibde…

Ìgbìmọ̀ Aláṣẹ Nàìjíríà Buwọ́lù Tírílíọ̀nù Kán Lè Díẹ̀ Fún Àwọn Iṣẹ́ Àmáyédẹrùn Tí Orílẹ̀-èdè

Ìgbìmọ̀ àwọn Aláṣẹ tí Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà (FEC) tí fọwọ́sí tírílíọ̀nù kán lè díẹ̀ Náírà (N1.202) fún àwọn iṣẹ́ àkànṣe àmáyédẹrùn orílẹ̀-èdè pàtàkì bí iná mọna-mọna, Pápákọ́ Òfurufú, àti àwọn iṣẹ́ òpópó-ònà tí nlọ lọwọ́. ‎ ‎ Ìgbésẹ pàtàkì…

Àwọn Adarí Ẹgbẹ́ Òṣèlú PDP Ṣetán Ìpàdé Ìgbàlà Ọmọ Ẹgbẹ́ Kúrò Lọ́wọ́ Ìsákiri Lọ Inú Ẹgbẹ́ Òṣèlú Míràn

Gómìnà àti gómìnà tẹ́lẹ̀rí lábẹ́ òṣèlú ẹgbẹ́ People’s Democratic Party (PDP) péjọpọ̀ si ìlú Abuja láti wà ọ̀nà àbáyọ sì ìsákiri àwọn ọmọ ẹgbẹ lọ sin ẹgbẹ́ òṣèlú mìíràn. Àwọn to peju pèsè síbi ìpàde náà láti ri,…

Mínísítà gbóríyìn fún Ààrẹ bí ó se ka àwọn iṣẹ́ àkànṣe tí yóò ṣíṣọ lójú rẹ̀…

Mínísítà Nàìjíríà fún olú ìlú (FCT), Ọ̀gbẹ́ni Nyesom Wike, ti ṣàlàyé pé Abuja ti rí àyípadà tó lápẹẹrẹ lábẹ́ ìṣàkóso Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu. Mínísítà sọ eyi di mimọ lasiko abẹwo ibojuto iṣe Akanṣe opopona…
button