Browsing Category
KÓKÓ INÚ ÌRÒYÌN
This is a category for featured story
Àjọ NELFUND Bẹ̀rẹ̀ Pinpin Owó Àlàkalẹ̀ Ti Oṣù Kẹrin
Àjọ Nigerian Education Loan Fund (NELFUND) ti bẹ̀rẹ̀ pinpin Owó ẹ̀yá àlàkalẹ̀ ti Oṣù Kẹrin ọdún 2025 fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó peregede fún un jákèjádò Nàìjíríà.
Àkọsílẹ̀ láti ọdọ Alakoso àjọ Strategic Communications owó náà, Ìyáàfin Oseyemi…
Mínísítà Ọ̀rọ̀ Nípa Àwọn Obìnrin Kí Ọpẹ́yẹmí Bright Kú Oríire Oyè Mayor.
Mínísítà tó ń ri sì ọ̀rọ̀ nípa àwọn Obìnrin, Hajiya Imaan Sulaiman-Ibrahim ti kí Princess Opeyemi Bright ku oríire bí o ti fìtàn balẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọ̀dọ́mọdebìnrin tó kéré jùlọ Mayor ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì.
Bí ètò ifinijoye rẹ yóò ṣe…
Ẹgbẹ́ Òṣèlú PDP Ní Ìlà Oòrùn Gúsù Ti Kìlọ Látàrí Ìpè Ìpàdé Àwọn Alẹ́nulọ́rọ̀ Tó Jẹ́ Òfegè
Ẹgbẹ́ Òṣèlú PDP Ní Ìlà Oòrùn Gúsù ti kìlọ fún àwọn ọmọ ẹgbẹ́ rẹ̀ láti má ka ìpè ipàdé pàjáwìrì àwọn alẹ́nulọ́rọ̀ ní Abuja sí.
Nínú àkọsílẹ̀ ìròyìn kan, alukoro ẹgbẹ́ ní ẹ̀ka ìlà oòrùn gusu, Chigozie Igwe, tẹnumọ…
Burna Boy Yóò Se Eré Ọ̀fẹ́ Fún Àwọn Ololufẹ Rẹ̀ Ní Orílè-èdè Burkina Faso
Ìràwọ akọrin ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà sọ èyí di mímọ̀ lórí ẹ̀rọ ayélujára Instagramu rẹ̀ ni ọjọ́ kẹtàdínlogun oṣù kàrún ọdún 2025 pé òun ṣe eré ní orílẹ̀-èdè Burkina Faso.
"Ti o bá seése, fún mi, iyì ni yóò jẹ fún mi láti seré ọ̀fẹ́…
Nàìjíríà Yóò Gbàlejò Àwọn Ilé iṣẹ́ Ọkọ̀ Oníná Tí China
Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí ṣètò láti gbàlejò àwọn ilé-iṣẹ́ ọkọ̀ ayọkẹlẹ oníná bí Orílẹ̀-èdè China tí n kéde ìpinnu wọ́n.
Aṣojú Ilú China sí Nàìjíríà, Yu Dunhai, sọ èyí l'àkókò àbẹwò kán sí Mínísítà fún Àwọn òun alumọni tó lágbára tí…
Ààrẹ Nàìjíríà Ṣàtúnṣe Ìgbìmọ̀ Eré Ìdárayá Orílẹ̀-èdè Fún Ìlọsíwájú
Ààrẹ Bola Tinubu kéde àtúnṣe tí Ìgbìmọ̀ Eré Ìdárayá tí Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà (National Sports Commission NSC) tó tí wá fún ìgbà pípẹ́ láti dáàbòbo ìṣàkóso eré ìdárayá kúrò lọ́wọ́ àwọn ìdádúró ìjọba àti àwọn ìdíwọ́ mìíràn.
Ààrẹ ló sọ…
NGO ní òun ti ní ipa lórí àwọn ènìyàn méjìlé-lọ́gbọ̀n Mílíọ́nù ní abala ìtọ́jú…
Ilé iṣẹ́ tí kìí ṣe tìjọba kan, Nigeria Solidarity Support Fund, NSSF, ti sọ pé òun ti ní ipa lórí àwọn ènìyàn méjìlé-lọ́gbọ̀n Mílíọ́nù ní ọdún mẹ́rin tí òun ti ń ṣiṣẹ́ ní abala ìtọ́jú ìlera lórílẹ̀-èdè.…
Ọ̀sẹ̀ Àṣà Ìlú Ìbàdàn Tí 2025: Makinde Ṣèlérí Láti Fún Àwọn Olórí Ìlú Ní Ẹ̀tọ́ Wọn.
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti ṣèlérí pé ìṣèjọba òun kò ní fi ẹ̀tọ́ àwọn olórí ìlú dùn wọ́n.
Gómìnà ló sọ ọ̀rọ̀ yii di mímọ̀ níbi àṣèkágbá ayẹyẹ ọsẹ̀ àṣà ìlú Ìbàdàn to wáyé ni pápá ìṣeré Obafemi Awolowo, ni agbègbè Òkè-Ado, ni ìlú…
Olùdíje Gómìnà fún ẹgbẹ́ LP Anambra bẹnu àtẹ́ lu pípa Agbẹjọ́rò
Olùdíje Gómìnà fún ẹgbẹ́ òṣèlú Labour (LP), ti ìpínlẹ̀ Anambra, Ọ̀gbẹ́ni George Moghalu, ti bẹnuàtẹ́ lu ìṣẹ̀lẹ̀ aburú pí́pa Ààrẹ- gbogbogbòò agbègbè Aguleri ti agbègbè ìjọba ìbílẹ̀ Gusu Anambra, Ọ̀gbẹ́ni Ifeanyi…
Hajj 2025: Kwara gbé àwọn arìnrìn àjò mímọ́ ikọ̀ ẹlẹ́ẹ̀kẹta ti ẹdẹ̀ẹ́gbẹ̀ta-ó-lé-ọgọ́ta Lọ…
Ikọ̀ ẹlẹ́ẹ̀kẹta àwọn arìnrìn àjò mímọ́ tí ó tó ẹdẹ̀ẹ́gbẹ̀ta -ó -lé -ọgọ́ta láti ìpínlẹ̀ Kwara gbéra lọ sí Saudu Arabia ní ọjọ́ Àbámẹ́ta láti ṣe iṣẹ́ mímọ́, tí ó sì jẹ́ pé ọkọ̀ òfurufú Max ni ó gbé wọn láti…