Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌDÓKOÒWÒ
This is a category for business news
Ìlàkààkà Ààrẹ Tinubu Láti Mú Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Dé Ilẹ̀ Ìlérí Ń So Èso Rere-…
Mínísítà Fún Ohun Àlùmọ́ọ́nì, Ọ̀gbẹ́ni Dele Alake àti Gomina Ìpínlẹ̀ Kaduna Uba Sani ti sàpèjúwe ìgbésẹ̀ ìsèjọba Ààrẹ Bọla Tinubu gẹ́gẹ́ bí èyí tí yóò mú ìyípadà ọ̀tun bá Orílẹ̀-èdè, tí yóò sì sọ ayé…
Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ní Ohun Àmúyẹ Fún Ìdàgbàsókè Ọrọ̀ Ajé: Igbákejì Ààrẹ…
Ìjọba Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti késí àwọn olùdókòwò ilẹ̀ òkèèrè láti darapọ̀ mọ́ ètò ọrọ̀ ajé Orílẹ̀-èdè náà èyí tí ó ti ń rú gọ́gọ́ sí i, èyí tí yóò mú ìgbòòrò bá ìdókòwò wọn àti ọrọ̀ ajé…
Ìbásepọ̀ Tí Ó Múná Dóko Wáyé Láàrin Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Àti Botswana
Igbákejì Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Naijiria, Kashim Shettima ti sèpàdépọ̀ pẹ̀lú Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Botswana, Duma Boko, èyí tí ó wáyé ní Davos, Orílẹ̀-èdè Switzerland, níbi tí wọ́n ti ní ìfẹnukò lórí àwọn ohun tí yóò…
Iréwọlédé, Ẹ Máa Jó Jàgíní-yòdò: Ìjọba Àpapọ̀ Sàgbékalẹ̀ Ilé Iṣẹ́ Fún Ẹ̀yáwó Láti…
Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu ti sàdéhùn láti mú ìdàgbàsókè bá ìgbáyégbádùn ọmọ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà pẹ̀lú ìsàgbékalẹ̀ ilé iṣẹ́ ètò ẹ̀yáwó
Ìgbésẹ̀ náà wáyé láti mú ìgbòòrò bá ẹka ètò…
Ìdùnnú Subú Lu Ayọ̀ Ní Ìlú Abuja Nígbà Tí Ààrẹ Tinubu Ń Pín Oúnjẹ Fún Àwọn…
Ariwo ayọ̀ ń jáde lẹ́nu àwọn ènìyàn nígbà tí Mínísítà Fún Ọ̀rọ̀ Àwọn Obìnrin, Ọnọrébù Imaan Sulaiman-Ibrahim ń pín oúnjẹ fún àwọn Obìnrin ní Ìlú Abuja, èyí tí ó wà lára ètò àlàkalẹ̀ fún ayẹyẹ ìparí…
Ọ̀wọ́ngógó Owó Ọjà Yóò Di Àfìsẹ́yìn Tí Egúngún Ń Fi Aṣọ Ní Ọdún 2025- Ààrẹ Sọ̀rọ̀…
Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu fi àrídájú hàn pé Òun yóò mú àdíkù bá fífi ọ̀pọ̀lọpọ̀ owó ra ọjà kékeré ti o n waye ni Orilẹ-ede Naijiria láti ìdá mẹ́rìnlélọ́gbọ̀n nínú ọgọ́rùn-ún (34%) sí ìdá mẹ́ẹ̀dóógún nínú…
Ẹ Gbọ́lá Fún Àwọn Ohun Èlò Tiwa-n-tiwa: Ìjoba Àpapò Pàrọwà Sí Ará Ìlú
Ìjọba àpapọ̀ ti sàlàyé pàtàkì rírà àti bíbu ọlá fún àwọn ohun èlò tiwa-n-tiwa, lójúnà àti mú ìdàgbàsókè bá ètò ọrọ̀ ajé Orílẹ̀-èdè Naijiria
Ìpè náà wáyé láti ọ́ọ́fìsì akọ̀wé ìjọba…
Gómìnà ìpínlẹ̀ Kwara Buwọ́lù Lu Àfikún Owó Fún Àwọn Òṣìṣẹ́.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Kwara AbdulRahman Abdulrazak ti Buwọ́lù àfikún owó fún àwọn òṣìṣẹ́ ìpínlẹ̀ náà pátá pátá.
Ó ní láti fi di àwọn àfikún owó ẹyin tó yẹ ki ijoba san fún àwọn òṣìṣẹ́ ni oun se Buwọ́lù lu ìwé náà àti láti mú inú àwọn òṣìṣẹ́…
Àpò Ìfowópamọ́ Owó Epo Àìfọ̀ Nàìjíríà Ti Súnmọ́ Ẹ̀ẹ́dẹ̀gbeta Dọ́là
Àjọ National Economic Council ti jẹ ko di mímọ pe Àpò Ìfowópamọ́ Owó Epo Àìfọ̀ Nàìjíríà ti wà ni oye to súnmọ́ Ẹ̀ẹ́dẹ̀gbeta Dọ́là - $473,734,57 titi di ọjọ Kọkànlélọ́gbọ̀n osù Kẹwàá, ọdún 2024.
Alága ẹgbẹ́ àwọn Gómìnà ni…
Soludo Pè Fún Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ Láti Sàgbékalẹ̀ Ètò Ọrọ̀ Ajé Èyí Tí Yóò Fìdí Múlẹ̀…
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Anambra, Ọ̀jọ̀gbọ́n Charles Soludo ti ké sí tolórí-tẹlẹ́mù láti fọwọ́sowọ́pọ̀ fún ìsàgbékalẹ̀ ètò ọrọ̀ ajé tí ó múná dóko
Ó pe ìpè náà níbi àpérò kan tí ó wáyé ní ìlú Abuja…