Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌDÁRAYÀ
This is a category for sport news
Ìpínlẹ̀ Enugu Gbá Imọlẹ̀ Ìṣọ̀kan Ìdárayá Tí Orílẹ̀-èdè
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Enugu, Peter Mbah, tí gbá imọlẹ̀ ìṣọ̀kan tí èrè ìdárayá àpapọ̀ (National Sports Festival), l'àkókò tó ṣé ìlérí ìkópa kíkún tí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ tí ìpínlẹ̀ rẹ̀ nínú èyí tó mbọ, tí yóò wáyé ní Ìpínlẹ̀ Ogun, Nàìjíríà.
Mbah,…
Wọ́n Sin Òkú Balógun Ikọ̀ Rangers Tẹ́lẹ̀ri, Isiadinso Ni Ìpínlẹ̀ Anambra
Wọ́n ti sin Òkú Balógun Ikọ̀ Rangers Intl FC ti Enugu tẹ́lẹ̀rí ní ọjó Ojoru ní ìlú rẹ, Obeagu Osili. Njikoka, ìjọba ibilẹ Anambra, ipinlẹ Anambra.
Agbabọ́ọ̀lù teleri náà ló jẹ balogun iko Rangers laarin odun 1981 sì 1984, o ku ni ojo…
Wọ́n Dá Ọmọ Ẹgbẹ́ Ìgbìmọ̀ FIFA Tẹ́lẹ̀rí Sílẹ̀
Ọmọ ẹgbẹ́ igbimọ FIFA teleri. Mamoutou Toure ní wọn ti dá silẹ lẹ́wọ̀n ní Mali bayii lẹyin nǹkan bí ọdún Méjì ní àtìmọ́lé latari ìwà àjẹbánu bí àwọn oníròyìn Málì ṣe sọ ní ọjó Ọjọ́rú.
Ọgbẹni Touré tó jẹ ààrẹ àjọ eré Bọ́ọ̀lù…
Látàrí Rúkè-rúdò Tí Ó Wáyé Lásìkò Eré Ìdárayá : Àjọ NPFL Jẹ Ẹgbẹ́ Agbábọ́ọ̀lù…
Àjọ Alákòso Ẹgbẹ́ Agbábọ́ọ̀lù Abẹ́lé ti Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti jẹ Ẹgbẹ́ Agbábọ́ọ̀lù El-Kanemi níyà látàrí bí wọ́n se kùnà láti se ètò tí ó múná dóko lásìkò ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ tí ó wáyé láàrin ẹgbẹ́…
Àjọ CAA Yan Afunfèrè Rẹfirí Ọmọ Nàìjíríà Fún Ìdíje Tí Ọjọ́ Orí Àwọn Akópa Kò Kọjá Ogún Ọdún Ní…
Àjọ Confederation of Africa Athletics (CAA) ti yan Omatseye Nesiama tó jẹ́ adarí àjọ Athletics Federation of Nigeria (AFN) nígbà kan ri gẹgẹbí afunfèrè Rẹfirí ìdíje alápapọ̀ ẹlẹ́ẹ̀kẹta Adúláwọ̀ ti Ọjọ́ orí àwọn akópa kò kọjá Ogún Ọdún ti…
CAF ṣèdárò pẹ̀lú ẹbí Christian Chukwu
Ààrẹ Ìgbìmọ̀ Ẹgbẹ́ Agbábọ́ọ́lù Adúláwọ̀ (CAF), Dókítà Patrice Motsepe, ti ṣèdáro pẹ̀lú ẹbí Christian Chukwu, ènìyàn pàtàkì nínú eré bọ́ọ́lù Nàìjíríà àti ti Adúláwọ̀.
Dokita Motsepe fi ẹdun ọkan rẹ han…
Ògbóntàrigì Agbábọ́ọ̀lu Sísọ Lójú Ilé Iṣẹ́ Fíìmù Tuntun
Pẹ̀lú àjọṣepọ̀ Olùdarí ilẹ̀ gẹ̀ẹ́sì, Matthew Vaughn,Cristiano Ronaldo, ògbóntàrigì agbabọ́ọ̀lù ti kánlu agbami òwò ilé iṣẹ fíìmù, ó si ti sí ilé iṣẹ́ Fíìmù àdáni tó pè ní- UR•MARV.
Àjọṣepọ̀ yìí ti bí ṣíṣe àti níná owó lórí fíìmù…
Ikọ̀ Arsenal Ni Ìrètí Àti Gbadé Líìgì UEFA Champions
Ikọ̀ Arsenal kò ti kọjá sì ipò kíní ìdíje Líìgì UEFA Champions láti ọdún 2009, ṣùgbọ́n akọ́nimọ̀ọ́gbá wọn Mikel Arteta fẹ́ kọ ìtàn tuntun láti gbàá nígbàtí wọn bá kojú alátakò wọn, Real Madrid nínú ìgbésẹ̀ kíní ìdíje kòmẹsẹ̀óyọ…
Ìdíje NPFL: Ikọ̀ Rivers United Fẹ̀yìn Remo Stars Gbolẹ̀
Ikọ̀ Rivers United dí àlàfo díẹ̀ tó wà láàárín òun pẹ̀lú ikọ̀ Remo Stars nínú ìdíje Nigeria Premier League Football (NPFL) nípa fífi ẹ̀yìn wọn gbolẹ̀ pẹ̀lú ayò kan si òdo (1-0) ní pápá ìṣeré Adokiye Amiesimaka, Port-Harcourt,…
Aya Ààrẹ Àkọ́kọ́ Sí Idije Kílọ̀bù Bọ́ọ̀lù AÀfọwọ́gbá Ti Àwọn Obìnrin Ẹlẹ́ẹ̀kọkàndínlógójì
Ìdíje Kílọ̀bù Bọ́ọ̀lù àfọwọ́gbá ti àwọn Obìnrin ẹlẹ́ẹ̀kọkàndínlógójì ti bèrè ní ìlú Abuja ti aya ààrẹ, senetọ̀ Oluremi Tinubu, CON, ṣe iside rẹ ni pápá isere àpapọ MKO Abiola ti ìlú Abuja, Naijiria.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ololufẹ…