Browsing Category
KÓKÓ INÚ ÌRÒYÌN
This is a category for featured story
Gómìnà Aiyedatiwa Ṣàlékún ààbò jákè jádò Ìpínlẹ̀ Ondo
Gómìnà ìpínlè Ondo, Lucky Aiyedatiwa, ti pàse fún àwon elétò ààbò láti túnbọ̀ lékún ìpààrà lórí ààbò jákè kádò àwọn agbègbè àti agbègbè aginjù látàrí ìkọlù Àgọ́ ọlọ́pàá kan ní ìjọba ìbílẹ̀…
Nàìjíríà kí orílẹ̀ èdè Haiti kú oríire àjọ̀dún ọdún méjìlé-lógún- lénígba…
Mínísítà Nàìjíríà fún ọ̀rọ̀ òkèèrè, Aṣojú Yusuf Tuggar, ti kí Mínísítà fún ọ̀rọ̀ òkèèrè orílẹ̀ èdè Haiti, Jean-Victor Harvel Jean-Baptiste, ìjọba àti àwọn ènìyàn Haiti, kú́ oríire àjọ̀dún òmìnira wọn.…
Póòpù Leo Kẹrìnlá Kéde Láti Gba Àlàáfíà Láyè
Olórí Kátólíìkì, Póòpù Leo Kẹrìnlá, ti ké sí àwọn olórí l'àgbáyé, àwọn ìjọba àti àwọn aráàlú láti gba òun tó pè ní “àlàáfíà aláìlọ́wọ́ àti tí kò ní òun ìjà” gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà tí ó dájú jùlọ sí ìdúróṣinṣin àlàáfíà àgbáyé àti iyì ènìyàn.
…
Gómìnà AbdulRazaq Rọ Àwọn Aráàlú Láti Ṣ’àtìlẹ́yìn Fún-un Bí Ọdún 2026 Ṣé Bẹ̀rẹ̀
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kwara, Àárín Gbùngbùn Àríwá Nàìjíríà, AbdulRahman AbdulRazaq, ti ké sí àwọn aráàlú láti dúró ṣinṣin nínú àtìlẹ́yìn wọn fún ìṣàkóso rẹ̀ bí ọdún 2026 ṣé bẹ̀rẹ̀.
Ó ṣèlérí pé ìjọba yóò tẹ̀síwájú nínú ìsapá rẹ̀ láti mú…
Ààrẹ Tinubu Yín Hadiza Bala-Usman Ní Ọjọ́ìbí Ọgọ́ta Ọdún
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu tí gbóríyìn fún Olùdámọ̀ràn Pàtàkì rẹ̀ lórí Ìṣètò Ìlànà àti Olórí Ẹ̀ka Ìpèsè Àpapọ̀ Àárín Gbùngbùn (CRDCU), Hadiza Bala-Usman, fún iṣẹ́ ìjọba tó tayọ̀ nígbà tó ń ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ọgọ́ta ọdún rẹ̀.
Nínú…
Gómìnà Zulum Gbàlejò Ìpàdé Àsà Ti Kanem-Borno
Gomina ipínlẹ̀ Borno, Babagana Umara Zulum, ti gbàlejò ìpàdé ọ̀gọ̀rọ̀ ẹgbẹgbẹ̀run ẹ̀yà ènìyàn Kanuri ó kéré tán orílẹ-èdè mẹ́wàá láti Ilẹ̀ Adúláwọ̀ tó wá síbi ìpàde àṣà ti Kanem-Borno tó wáyé ní ìlú Maiduguri.
Ìpàdé náà ṣe àgbájọpọ̀…
Wọ́n Kọ̀ Láti Gbá’dúró Alátakò Ìjọba Ùgándà Kizza Besigye
Lẹ́yìn ọdún kan tí wọ́n ti mú un, ilé ẹjọ́ gíga orílẹ̀-èdè náà ti kọ̀ láti gbá òní'dúró alátakò Ìjọba Ùgándà Kizza Besigye kúrò nínú túbú.
Wọ́n ti fi ẹ̀sùn ìṣọ̀tẹ̀ kan Besigye nítorí pé ó gbèrò láti fi agbára mú ààrẹ Yoweri…
Lookman, Chelle Wà Lára Agbábọ́ọ̀lù Mọkànlá Tó Yarantí Jùlọ Tí Wọ́n Dárúkọ Ní Ìdíje AFCON Ọdún 2025…
Agbábọ́ọ̀lù ará ipò iwájú Super Eagles orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Lookman àti akọ́nimọ̀ọ́gbá, Eric Chelle ní wọ́n ti kéde pé wọ́n wà lára agbábọ́ọ̀lù mọkànlá tó yarantí jùlọ ní ìpele àkọkọ tí Idije Africa Cup of Nations (AFCON), Ọdun…
Ìtọ́nisọ́nà Ṣé Pàtàkì Sí Ìgboyà Láti Darí Gẹ́gẹ́bí Aṣáájú Dáadáa – Mínísítà
Mínísítà fún Ìròyìn àti Ìtọ́sọ́nà Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Mohammed Idris, ti tẹnu mọ́ ìmọ̀ràn àti ìtọ́sọ́nà gẹ́gẹ́ bí òun pàtàkì sí ìgboyà fún ẹnikẹ́ni láti darí bí aṣáájú réré.
Mínísítà fún Ìròyìn sọ ọ̀rọ̀ yìí níbi ìpàdé kan tí…
Gómìnà Nwifuru Gbóríyìn Fún Àwọn Àṣeyọrí Ni Orísirísi Ọnà Ni Ìpínlẹ̀ Ebony.
Gómìnà Francis Nwifuru ti gbóríyìn fún àwọn àṣeyọrí àti àwọn ìdàgbàsókè to sẹlẹ̀ ni ìpínlẹ̀ Ebony nipa ètò Ẹ̀kọ́ àti ìlera.
Nwifuru so èyí di mímọ̀ lásìkò to n ṣe idupẹ nile ìjósìn láti sààmì sí ayẹyẹ ọdun ìjọba awaarawa ni Abakaliki.…