Browsing Category
KÓKÓ INÚ ÌRÒYÌN
This is a category for featured story
Àwọn Ọmọ-ogun Ṣàfihàn Ẹní Tó Ń Ṣètò Ìpara-ẹni Láàrin Ìlú Ní Àríwá-Ìlà Oòrùn
Àwọn Ọmọ-ogun tó ń ṣiṣẹ́ ní Àríwá-Ìlà Oòrùn Nàìjíríà HADIN KAI (OPHK) tí fí Ọ́gbẹ́ni Shariff Umar hàn gẹ́gẹ́ bí ẹní tó ń ṣètò ìpara-ẹni láàrín ìlú pẹ̀lú ado olóró tó ṣẹ̀ṣẹ̀ wáyé, èyí tí àwọn Ológun náà tí gbìyànjú láti dúró.
Èyí ni…
Ààrẹ Tinubu Pàṣẹ Pé Kí Wọ́n Bẹ̀rẹ̀ Sí Máa Wá Àwọn Tó Ṣékọlù Kasuwan Daji
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu tí pàṣẹ fún Mínísítà fún ààbò, Olórí Àwọn Ológun, Àwọn Olórí Gbogbo Àwọn Ọmọ Ológun, Olórí Àwọn Ọlọ́pàá, àti Olùdarí Àgbà ti Ẹ̀ka Àwọn Iṣẹ́ Ìpínlẹ̀ (DSS) láti wá àwọn tó ṣe ìkọlù sí Kasuwan Daji kí wọ́n sì mú wọn ní…
Àwọn ọmọ ológun ti gba àwon ará ìlú tí wón jí gbé ní ìpínlẹ̀ Borno sílẹ̀
Àwọn ọmọ-ogun ti Operation HADIN KAI (OPHK) tún ti ṣe àṣeyọrí pàtàkì mììràn lẹ́nu iṣẹ́ wọn, nígbà tí wọ́n farabalẹ̀ kán lu àwọn oníjàgídíjàgan kan ní ìjọba ìbílẹ̀ Konduga, ti Ìpínlẹ̀ Borno, léèyí tí ó yọrí…
Gómìnà ìpínlẹ̀ Niger ṣèdárò àwọn afaragbà Borgu
Gómìnà ìpínlẹ̀ Niger, Àringbùngbùn Arewa Nàìjíríà, Mohammed Umaru Bago, ti banújẹ́ lórí ìkọlù àwọn oníjàgídíjàgan tí ó ṣẹlẹ̀ láìpẹ́ yìí ní agbègbè ìjọba ìbílẹ̀ Borgu, ti ìpínlẹ̀ náà, tí ó sì ń…
Ẹgbẹ́ ran àwọn tó ye ààrun jẹjerẹ ọyàn bọ́ lọ́wọ́ ni Anambra
Ẹgbẹ́ àwọn obìnrin ìpínlẹ̀ Anambra, ní Amẹ́ríkà Inc. àti Ẹgbẹ́ obìnrin ìpìnlẹ̀ Anambra ti Amẹ́ríkà tí ń rí sí Àjọṣepọ̀ lórí ààrùn jẹjẹrẹ ní Nàìjíríà, ti ṣàkójọ owó tó tó mílíọ́nù náìrà mẹ́ta láti ran…
Ààrẹ Tinubu Ṣèpàdé Pẹ̀lú Paul Kagame Ní Paris
Ààrẹ Bola Tinubu ti ṣé ìpàdé bóǹkẹ́lẹ́ pẹ̀lú Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Rwanda, Paul Kagame, ní Paris, France, níbi tí àwọn olórí méjèèjì ti jíròrò àwọn ọrọ àgbáyé àti tí Áfíríkà.
Ìpàdé bóǹkẹ́lẹ́ náà jẹ́ ìgbà àkọ́kọ́ ti Ààrẹ Tinubu tí yóò…
Ilé-Iṣẹ́ Ọkọ̀ Ojú Irin Nàìjíríà Bẹ̀rẹ̀ Déédé Owó Ojú-Irin
Ilé-Iṣẹ́ Ọkọ̀ Ojú-Irin Nàìjíríà (NRC) ti fi dá àwọn arìnrìn-àjò lójú pé wọ́n ń gbìyànjú láti mú kí iṣẹ́ ọkọ̀ ojú irin dára síi, ìtùnú, àti ààbò lórí gbogbo iṣẹ́ ọkọ̀ ojú irin bí wọn ṣe bẹ̀rẹ̀ déédéé owó ọkọ ojú irin náà ní ọjọ́ Àìkú, ọjọ́…
Agbábọ́ọ̀lù Gueye Jẹ́ kí Ikọ̀ Senegal Wọ Ipele Kẹta Tó Kángun Sí Àsekágbá Ìdíje AFCON
Ògbóntàrigi agbábọ́ọ̀lù ní ipò àárín fún ikọ̀ Senegal, Pape Gueye sọ bọ́ọ̀lù ní igbà méjì sínú àwọ̀n nígbà ti ikọ̀ Senegal jà raburabu látẹ̀yìn wá láti lu ikọ̀ Sudan ní ayò mẹ́ta sí oókan(3-1) ní ìpele kẹta tó kángun sí àsekágbá ìdíje…
Malawi Fagilé Owó Ilé-ẹ̀kọ́ Gírámà
Ìjọba Malawi tí kéde pé a tí fagilé owó pàtàkì ní àwọn ilé-ẹ̀kọ́ gírámà, láti ọjọ́ kìíní oṣù kìíní ọdún 2026, ní ìgbésẹ̀ kan tí a gbé kalẹ̀ láti mú kí ọ̀nà ẹ̀kọ́ gbòòrò sí i jákèjádò Orílẹ̀-èdè.
Ilé-iṣẹ́ Ẹ̀kọ́ jẹ́rìí sí i pé a ti…
Peter Obi darapọ̀ mọ́ ADC fún ìdìbò ọdún 2027
Olùdíje fún ipò Ààre ti ẹgbẹ́ Labour ní ọdún 2023, Ọ̀gbẹ́ni Peter Obi, ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ African Democratic Congress (ADC), ẹgbẹ́ òṣèlú ìṣọ̀kan, fún ìdìbò gbogbogbòò 2027.
Obi kede ifi ẹgbẹ rẹ silẹ ni Ọjọọru, ọjọ…