Browsing Category
KÓKÓ INÚ ÌRÒYÌN
This is a category for featured story
Ààrẹ Tinubu Yóò Wà Níbi Ìfinijoyè Pope Leo Ẹ̀lẹ́ẹ̀kẹrìnlá
Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Naijiria, Bola Ahmed Tinubu yóò kúrò ní Abuja lọ sí Rome ti ṣe Olu ìlú Italy ní ọjọ́ Àbámẹ́ta láti jẹ ìpè ti wọ́n pèé fún ayẹyẹ Ìfinijoyè Pope Leo Ẹ̀lẹ́ẹ̀kẹrìnlá.
Pope Leo Ẹ̀lẹ́ẹ̀kẹrìnlá tile sọ pé òun nífẹ̀ẹ́ orílè-èdè…
Nàìjíríà Jẹ̀jẹ́ Àtìlẹ́yìn Fún Zambia
Ìgbákejì ààrẹ orílẹ̀-èdè yìí Kashim Shettima ti sọ pé ilẹ̀ olominira Zambia àti Naijiria ti jọ wà tipẹ́ nípa ọlörẹ́sọ̀rẹ́, àti pé ìjọba ààrẹ Bola Tinubu ti ṣetan láti tun jẹ kí àjosépọ̀ wọn tubọ máa tèsíwájú.
Ìgbákejì ààrẹ sọ…
Ààrẹ Nàìjíríà Tí Fọwọ́sí Gbígba Àwọn Ẹ̀ṣọ́ Igbó
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu tí fọwọ́sí ìgbanísíṣẹ́ tí àwọn ẹ̀ṣọ́ igbó gẹ́gẹ́bí isọdọtun àwọn ìlànà orílẹ̀-èdè láti ní Ààbò àti gbá àwọn igbó Nàìjíríà pàdà lọwọ́ àwọn ọ̀daràn àti àwọn arufín ilú.
Ìpinnu náà ní èròngbà látí tẹra mọ iṣẹ́…
Nàìjíríà Ṣé ìfihàn Ìgbésẹ̀ Àtúnṣe Òfin Tí Ọọ̀ràn-Orí-Ayélujára
Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí n ṣé àfihàn ìgbésẹ̀ àtúnṣe tí Òfin Ọọ̀ràn-Orí-Ayélujára, gẹ́gẹ́bí Mínísítà fún ìròyìn àti Àlàyé tí Orílẹ̀-èdè, Mohammed Idris, ṣé ìdánilójú imurasilẹ ìjọba láti ṣiṣẹ́ pẹ̀lú àwọn ilé-ìgbìmọ̀ aṣòfin tí Orílẹ̀-èdè, àwọn…
Àìsàn Lassa: Àjọ WAHO Tú Kun Ọjọ́ Gbígba Abéré Àjẹsára.
Àjọ ẹlẹ́tọ̀ ìlera ti wọn pẹ ni West Africa Health Organizations (WAHO) tí fi ọjọ́ kun gbígbà abẹrẹ ajẹsara nípa àìsàn Lassa fever kàkà kiri àgbáyé.
Ní ìlú Abuja ni ọ̀rọ̀ náà ti jáde ni ọjọ́rú láti ẹnu ọ̀gbẹni Alábá Balogun tó jẹ alukoro…
Ó Léwu Láti Ṣe Ìtójú Ará Yìí Ẹ Ló Sì Ilé ìwòsan Fún Ìtọ́jú Tó Péye: Àwọn Onímọ̀
Ààrẹ fún ìtọ́jú agbègbè àti ìlera àwọn ènìyàn Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà (EPHPAN) Dọ́kita Samuel Akingbehin ti wọn jẹ onimọ ati olùtújù agbegbe ti ṣe ìkìlọ àti ewu tó wà nínú ki àwọn ènìyàn má ṣe ìtọjú ará wọn Lai gbà aṣẹ lọwọ Oníṣègùn òyìnbó.…
Ìpínlẹ̀ Kaduna: Àwọn Ènìyàn Ìpínlẹ̀ Náà Parapò Láti Ṣe Àjoyọ́ Ọjọ́ Àlàáfíà.
Àwọn ará agbègbè ìpínlẹ̀ Kaduna ti pejo láti ṣe àfihàn ifẹ, irepo àti ìsọkan láàrin ara wọn ní ojọ́ kerindinlogun oṣù kàrún ọdún, 2025.
Ààrẹ ẹgbẹ́ àlàáfíà ti onigbagbọ wọn pẹ ni PRRFON alàgbà Buru kí àwọn ènìyàn tó jẹ Musulumi káàbò sí…
Ilé Ifowopamọ ECOWAS Ti Ṣetán Láti Sí Ilè Ifowopamọ Si Orílè-èdè Cote d’voire.
Ilé Ifowopamọ ECOWAS fún ìdọ́kọ̀wọ̀ àti ìdàgbàsókè ti buwolu ìwé ajọṣepọ láti da ilé iṣé silẹ ni Orílẹ̀-èdè Cote d'Ivoire.
Ni ìlú Abidjah ni ọrọ àjọsọpọ tó dan mọ́rán yii wáyé láàárín ìjọba Orílẹ-èdè Cote d'Ivoire èyí tí Mínísítà fún òrò…
Ààrẹ Tinubu Gbé Òsùbà O káre Fún Oníròyìn Àgbà Bisi Olatilo Fún Àádọta Ọdún Lẹnu Iṣé Ìròyìn.
Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Bola Ahmed Tinubu ti gbé Òsùbà o káre fún Aláṣẹ àti Olùdarí ilé iṣé Biscom Communication, Ọmọba Bisi Olatilo fún ayẹyẹ àádọta ọdún lénu iṣé ìròyìn.
Ààrẹ gbóríyìn fún ọmọba Olatilo fún akitiyan, ipá mọra, ìfẹ àti…
Ètò Ìlera Ọ̀fẹ́: Makinde Ṣíde Ìfilọ́lẹ̀ Ìlera Ọ̀fẹ́ Ní Ìjọba Ìbílẹ̀ Àríwá/Ìlà-Oòrùn Ìbàdàn.
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti jẹ ko di mímọ̀ pé ìṣèjọba òun yóò tẹ síwájú láti máa pèsè ètò ìlera lójúnà àti ri dájú pé ará ìlú wa ni ìlera pípé eléyìí tí yóò mú kí ọrọ̀ ajé rú gọ́gọ́ síi, ti ìṣẹ yóò sì dínkù ni àwùjọ.
Makibde…