Browsing Category
ÌRÒYÌN YÀJÓ-YÀJÓ
This is a category for TRENDING NOW
Àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ Naijiria bèèrè fún Ìṣojú nínú ìgbìmọ̀ NELFUND
Ẹgbẹ́ àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ Naijiria lapapọ, NANS, ti bèèrè fún Ìṣojú nínú apejọ ìgbìmọ̀ tí ń rí sí Owó yíyá fún Ẹ̀kọ́ ní Nàìjíríà, NELFUND, pé bí àwọn ṣe jẹ́ olùjàǹfààní àkọ́kọ́ fún owó yíyá náà, wọ́n…
Mínísítà kí Ìyáàfin Tinubu kú oríire fún yíyàn án ní ọmọ ẹgbẹ́ ìgbìmọ̀ Alákòóso…
Mínísítà fún Ọ̀rọ̀ àwọn Obìnrin, Imaan Sulaiman-Ibrahim, ti kí Arábìnrin kìíní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Sẹnetọ Oluremi Tinubu, lóríi bí wọ́n ṣe yàn án ní ọmọ ẹgbẹ́ ìgbìmọ̀ Alákòóso àwọn Arábìnrin Àkọ́kọ́…
Arábìnrin Kìínní Nàìjíríà di ọ̀kan lára ọmọ ẹgbẹ́ ìgbìmọ̀ alákòóso OAFLAD
Wọ́n ti yan Arábìnrin Kìínní Nàìjíríà, Oluremi Tinubu gẹ́gẹ́ bí ọmọ ẹgbẹ́ igbìmọ̀ Alákòóso fún Àjọ àwọn Arábìnrin kìíni fún Ìdàgbàsókè (OAFLAD), ipele Ìṣàkóso tó ga jùlọ nínú ẹgbẹ́ náà.
Eleyi waye…
Ààrẹ Tinubu kópa nínú apejọ gbogbogboò AU elẹ̀ẹkejì-dín-lógójì
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu ti kópa nínú apejọ awọn olori orilẹ-ede ti AU elẹ̀ẹkejì-dín-lógójì ní Addis Ababa.
Aarẹ Tinubu pẹlu Arabinrin kinni, Oluremi Tinubu ti kopa ninu apejọ ti akọle rẹ rẹ jẹ: idajọ ododo fun awọn Adulawọ and…
Erín Wo: Makinde Kẹ́dùn Adarí Afẹ́nifẹ́re, Olóyè Ayọ Adebanjọ Tó Papòdà
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti kẹ́dùn ikú adarí ẹgbẹ́ Afẹ́nifẹ́re, Olóyè Ayọ Adebanjọ, nígbà tó fi ikú rẹ̀ wé ìrókò nla to ṣubú ni ijù.
Makinde, ẹni tó fi ìpapòdà Olóyè Adebanjọ we òpin sáà kan, tó sì fi oloogbe náà wẹ ẹni nlá,…
Abúgbàmù Kankan kò wáyé ní ilé ìfọpo Warri – NNPCL
Ilé iṣẹ́ tí ń rísí ọ̀rọ̀ epo ilẹ̀ lórílẹ̀-èdè (NNPC), ti tako ìròyìn abúgbàmù ní ilé iṣé ìfọpo Warri (WRPC), tí wọ́n sí ṣàlàyé pé àwọn àtúnṣe ètò tó máa ń wáyé lóórè kóòrè nílé iṣẹ́ náà ló ń lọ…
Ààrẹ Tinubu ṣàjọyọ̀ pẹ̀lú ògbóhùntarìjgì òṣèré Nkem Owoh ní ààdọ́rin ọdún
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu ti kí ògbóhùntarìjgì òṣèré Nollywood, apanilẹ́ẹ́rín,akọrin tí ó tún jẹ́ olukọ̀ọ orin, Ọ̀gbẹ́ni Nkem Owoh, MON, bí ó ṣe ń ṣe ọjọ́ ìbí ààdọ́rin ọdún rẹ̀.
Lori ajọyọ naa, aarẹ Tinubu gboriyin…
Ilé iṣẹ́ ìjọba tí ń rísí ọ̀rọ̀ àwọn obìnrin yóò ṣàgbékalẹ̀ ìlànà ilé ìfowópamọ́…
Ilé iṣẹ́ ìjọba tí ń rísí ọ̀rọ̀ àwọn obìnrin ní Nàìjíríà yóò ṣàgbékalẹ̀ ìlànà ilé ìfowópamọ́ alábọ́ọ́dé lórílẹ̀-èdè fún àwọn olùṣòwò jákèjádò Nàìjíríà.
Minisita fun ọrọ awọn obinrin, Imaan…
Ìjọba Nàìjíríà túnbọ̀ fìdí ìpinnu rẹ̀ lórí ìrìnàjò lọ sílùú mìíràn lọ́nà…
Ìjọba Nàìjíríà ti túnbọ̀ fìdí ìpinnu rẹ̀ láti ri pé àwọn ìrìnàjò láti Nàìjíríà lọ sí àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn wáyé lọ́nà tó bòfin mu múlẹ̀, tí ó sì ṣàlàyé àǹfààní ọrọ̀ ajé àti ìdábòbò…
APC ṣe ìfilọ́lẹ̀ ìgbìmọ̀ ìpolongo fún ìdíje ìpo Gómìnà Chukwuma
Ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress (APC), ní ìpínlẹ̀ Anambra ti ṣe ìfilọ́lẹ̀ gbangba àwọn alákóso ìjọba ìbílẹ̀ fún agbègbè ìjọba àpapọ̀ Àringbùngbùn ti Anambra fún ìpolongo ìdìbò abẹ́lé fún Paul Chukwuma, ní…