Browsing Category
ÌRÒYÌN ÈTÒ Ọ̀GBÌN
Ètò Ohun Ọ̀gbìn Kòkòrò Tó Sí Ilẹ̀kùn Fún Iṣẹ́.:Onyema.
Igba Kejì Gómìnà ìpínlẹ̀ Delta Onyema ni ọjọ́ ajé sọ wí pé iṣẹ́ tí ohun ọ̀gbìn n ṣe láàrín ìlú ki ṣe kékeré rárá, nitori o jẹ ọ̀nà tí ènìyàn fi ri iṣé pẹ̀lú.
Ó sọ èyí di mímọ̀ nígbà tí ẹgbẹ́ àwọn àgbẹ̀ tí wọn pè Coalition of Delta ṣe…
Àwọn Àgbẹ̀ Òní kòkó Ti Ìpínlẹ̀ Ondo Fí Ẹ̀dun Ọkàn Wọn Hàn Látàrí Bí Àwọn Onísé Láabi Ṣe N Dá Wọn…
Àwọn àgbẹ̀ ọ̀gbìn kòkó ni ìpínlẹ̀ Ondo ni agbègbè Odigbo ni oko ti wọn pe Oluwa Forest ,ti fi ẹ̀dun ọkàn wọn ní hàn látàrí bi àwọn oníṣe láabi se n dá wọn Láàmú ninu oko
Wọn ní àkolù yìí bẹ̀rẹ̀ láti ìgbà tí ilé ẹjọ ti ṣe ìdájọ lori ìja…
Aláṣẹ pinnu láti wú àǹfààní abala nǹkan Ọ̀sìn síta
Alásẹ Akọ̀wé fún ètò Ọ̀gbìn àti ìdàgbàsókè ìgbèríko ti ìṣàkóso olú-ìlú, Lawan Kolo Geidam ti túnbọ̀ fìdí ìpinnu ṣíṣẹ ìwádìí àwọn ọ̀pọ̀lọpọ̀ àǹfààní tó wà nínú abala nǹkan Ọ̀sin fún ìfìdímúlẹ̀…
Ìpínlẹ̀ Kano Pinnu Àtìlẹ́yìn Fún Ètò Ẹtọ Ọmọnìyàn
Ìpínlẹ̀ Kano yóò máa ṣe àtìlẹ́yìn fún ìtẹ̀síwájú ohun gbogbo tó jẹ mọ́ ẹtọ ọmọnìyàn ni ìpínlẹ̀ náà.
Eléyìí di sísọ láti ẹnu onídàájọ àgbà àti Komisọ́na fún eto ìdájọ ìpínlẹ̀ kano, Barr. Haruna Isa Dederi níbi ti o ti n sojú fún…
Ilé iṣé Ìjọba Ti Ìpínlẹ̀ Kwara Se Ìdánilẹ́kọ̀ọ́ Fún Awọn Àgbẹ̀ Nípa Ọ̀gbìn Ẹ̀gẹ́.
Ó lẹ ní àádọ́ta àwọn àgbẹ̀ àti àwọn ènìyàn tí ó kópa nínú ìdánilékòó nípa ẹ̀gẹ́ gbin gbìn èyí wáyé láti mú ìdàgbàsókè bá ètò ounjẹ ni Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Ilé iṣé Ìjọba fún ètò ọgbin àti oúnjẹ ní o ṣe agbáterù ètò náà àti ìbáṣepọ̀ ìjọba…
Ìjì lile Tó Ṣẹlẹ̀ Ni Ìpínlẹ̀ Plateau Ṣe Ìjàmbá Sí Oko Adìye.
Ìjì líle tó ní agbára ti kolu ilé iṣé oko Adìyẹ ti o jẹ Dauda Mafala and Son ti o wà ni ìjọba ìbílẹ̀ Barkin ladi ni ìpínlẹ̀ Plateau ni ojó àbámẹ́ta, ti o sí pa àwọn adìye to lè ní ẹgbẹrun mẹta.
Ìṣẹlẹ yìí wáyé látàrí ójó ń là to bẹ sílẹ…
Ìpínlẹ̀ Niger Ba Orílẹ̀-èdè Morocco Da Ọrẹ Nípa Ohun Ọ̀gbìn.
Ìpínlẹ̀ Niger tí fí Orílẹ̀-èdè Morocco ṣe ọrẹ pàtàkì látàrí ọ̀rọ̀ ètò ọ̀gbìn, kí ànfààní ba wa fún ìdàgbàsókè àti ìlọsíwájú lórí ọ̀rọ̀ oúnjẹ.
Nígbà tí ó n sọ̀rọ̀ ní ìlú Abuja, Aṣojú Orílẹ̀-èdè Morocco sí Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Moha Ou Ali…
Ẹgbẹ́ Àwọn Àgbẹ̀ Rọ Ìjọba Láti Ní Ìbáṣepọ̀ Pẹ̀lú Àwọn Tọrọ Kán Fún Ààbò Tó péye Lórí Oúnjẹ.
Gbogbo ẹgbẹ́ àwọn àgbẹ̀ ni Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí rọ ìjọba àpapọ̀ láti ní ìbáṣepọ̀ pẹ̀lú ilé ìṣẹ́ ìjọba nípa ohun ọ̀gbìn àti láti ṣe ètò ààbò lórí oúnjẹ.
ọ̀mọ̀wé Fẹmi Oke, to jé alága fún ẹgbẹ́ náà ló sọ èyí ni ọjọ́rú ni ìlú Eko, nigba…
Ẹgbẹ́ NACP Gbóríyìn Fún Ìjọba Àpapọ Lórí Owó Ìrànlọ́wọ́ Epo Rọ̀bì.
Ẹgbẹ́ NACP to jẹ ẹgbẹ́ ohun ọ̀gbìn ti Gbóríyìn fún ìgbésẹ Ààrẹ Bọla Tinubu gbé lórí owó ìrànlọ́wọ́ epo rọ̀bì, o wà fí ànfààní náà, bẹ̀bẹ̀ wí pé kó ṣe ètò ààbò pípẹ́ fún àwọn àgbẹ̀ lákọ̀kọ̀ọ́ ti won ba wa nínú oko láti sí ṣẹ.
Ọ̀rọ̀ yìí…
Ìpínlẹ̀ Ebonyi Yóò Pín Ẹgbẹ̀rún Mẹ́tàlá Ajílẹ̀ Fún Àwọn Àgbẹ
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ebonyi sọ pé òun yóò pín ajílẹ̀ Ẹgbẹ̀rún Mẹ́tàlá fún àwọn àgbẹ ni ọ̀nà láti jẹ́ kí oúnjẹ pọ̀ yanturu.
Komisọ́na fún ìròyìn àti ìilani lọ́yẹ̀ ìpínlẹ̀ náà, Ògbẹ́ni Chikadibia Okpor, ló sọ èyí lẹ́yìn Ìpàdé…