Browsing Category
ÌRÒYÌN ÈTÒ Ọ̀GBÌN
Àwọn Tí Ó Ń Fi Owó Ṣe Ìrànlọ́wọ́ Fún Àwọn Ènìyàn Ṣe Ìrànlọ́wọ́ Fún Àwọn Àgbè Ni Ìpínlẹ̀ Enugu.
Ọgá àgbà pátápátá fún ilẹ iṣé Paschal -Rico, Olóyè Pascal Aneke àti Ọ̀gbẹni Sunday Ozokolo láti Orílẹ̀-èdè Switzerland ni ọjọ́ ìsinmi Pin àwọn ohùn èlò ìrànlọ́wọ́ fún àwọn àgbẹ̀ ìgbèríko ni ìjọba ìbílẹ̀ Ezeagu ni Ìpínlẹ̀ Enugu.
Àwọn…
Gómìnà ìpínlẹ̀ Borno Sọ Wí pé Ilẹ̀ Ẹ́ẹ̀kà Méje Ti Wà Nílẹ̀ Fún Ètò Ọ̀gbìn.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Borno Babagana Umara Zulum, ti ṣe àfihàn ilẹ̀ ẹ́ẹ̀kà méje fún ètò ọ̀gbìn labẹ ìjọba rẹ.
Ó ní ètò yìí wà fún àtìlẹ́yìn ìjọba Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu lórí ìrètí nlá fún Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Ó sọ èyí di mímọ̀ ni Mafa ni…
Àsìkò Ọ̀gbẹ Ilé: Mínísítà Ṣe Àyẹ̀wò Ounjẹ Wheat.
Mínísítà fún ètò ọ̀gbìn àti ààbò fún oúnjẹ (FMAFS) Ṣẹ́nitọ̀ Abubakar Iyari àti Mínísítà fún ìpínlẹ̀, Ṣẹ́nitọ̀ Aliyu Sani Abdullahi ṣe ìbẹ̀wò sí ọ̀gbìn oúnjẹ whaet ni ọjọ́ keje oṣù kọkànláọjọ́ fun ètò ọ̀gbìn ti ijoba àpapọ gbé kalẹ.
Ètò…
Àwọn tó nííṣe ṣe àyẹ́síi ìgbé ayé àwọn àgbẹ̀
Owó káríayé fún ìdàgbàsókè ètò ọ̀gbìn, IFAD-Ètò ìrànlọ́wọ́ àpapọ̀ iyì fún ìdàgbàsókè, VCDP, ti sọ pé ọdún mẹ́sàn án ti òhun ti wà ní ìpínlẹ̀ Ebonyi, Gúsù iwọ̀ oòrùn Nàìjíríà, ti ran ìgbé ayé…
Ètò Ohun Ọ̀gbìn Kòkòrò Tó Sí Ilẹ̀kùn Fún Iṣẹ́.:Onyema.
Igba Kejì Gómìnà ìpínlẹ̀ Delta Onyema ni ọjọ́ ajé sọ wí pé iṣẹ́ tí ohun ọ̀gbìn n ṣe láàrín ìlú ki ṣe kékeré rárá, nitori o jẹ ọ̀nà tí ènìyàn fi ri iṣé pẹ̀lú.
Ó sọ èyí di mímọ̀ nígbà tí ẹgbẹ́ àwọn àgbẹ̀ tí wọn pè Coalition of Delta ṣe…
Àwọn Àgbẹ̀ Òní kòkó Ti Ìpínlẹ̀ Ondo Fí Ẹ̀dun Ọkàn Wọn Hàn Látàrí Bí Àwọn Onísé Láabi Ṣe N Dá Wọn…
Àwọn àgbẹ̀ ọ̀gbìn kòkó ni ìpínlẹ̀ Ondo ni agbègbè Odigbo ni oko ti wọn pe Oluwa Forest ,ti fi ẹ̀dun ọkàn wọn ní hàn látàrí bi àwọn oníṣe láabi se n dá wọn Láàmú ninu oko
Wọn ní àkolù yìí bẹ̀rẹ̀ láti ìgbà tí ilé ẹjọ ti ṣe ìdájọ lori ìja…
Aláṣẹ pinnu láti wú àǹfààní abala nǹkan Ọ̀sìn síta
Alásẹ Akọ̀wé fún ètò Ọ̀gbìn àti ìdàgbàsókè ìgbèríko ti ìṣàkóso olú-ìlú, Lawan Kolo Geidam ti túnbọ̀ fìdí ìpinnu ṣíṣẹ ìwádìí àwọn ọ̀pọ̀lọpọ̀ àǹfààní tó wà nínú abala nǹkan Ọ̀sin fún ìfìdímúlẹ̀…
Ìpínlẹ̀ Kano Pinnu Àtìlẹ́yìn Fún Ètò Ẹtọ Ọmọnìyàn
Ìpínlẹ̀ Kano yóò máa ṣe àtìlẹ́yìn fún ìtẹ̀síwájú ohun gbogbo tó jẹ mọ́ ẹtọ ọmọnìyàn ni ìpínlẹ̀ náà.
Eléyìí di sísọ láti ẹnu onídàájọ àgbà àti Komisọ́na fún eto ìdájọ ìpínlẹ̀ kano, Barr. Haruna Isa Dederi níbi ti o ti n sojú fún…
Ilé iṣé Ìjọba Ti Ìpínlẹ̀ Kwara Se Ìdánilẹ́kọ̀ọ́ Fún Awọn Àgbẹ̀ Nípa Ọ̀gbìn Ẹ̀gẹ́.
Ó lẹ ní àádọ́ta àwọn àgbẹ̀ àti àwọn ènìyàn tí ó kópa nínú ìdánilékòó nípa ẹ̀gẹ́ gbin gbìn èyí wáyé láti mú ìdàgbàsókè bá ètò ounjẹ ni Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Ilé iṣé Ìjọba fún ètò ọgbin àti oúnjẹ ní o ṣe agbáterù ètò náà àti ìbáṣepọ̀ ìjọba…
Ìjì lile Tó Ṣẹlẹ̀ Ni Ìpínlẹ̀ Plateau Ṣe Ìjàmbá Sí Oko Adìye.
Ìjì líle tó ní agbára ti kolu ilé iṣé oko Adìyẹ ti o jẹ Dauda Mafala and Son ti o wà ni ìjọba ìbílẹ̀ Barkin ladi ni ìpínlẹ̀ Plateau ni ojó àbámẹ́ta, ti o sí pa àwọn adìye to lè ní ẹgbẹrun mẹta.
Ìṣẹlẹ yìí wáyé látàrí ójó ń là to bẹ sílẹ…