Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌLERA
This is a category for health news
Ẹgbẹ́ Ọmọ Ìlú Eko Ṣetán Láti Ṣe Ìrànlọ́wọ́ Ètò Ìwòsàn Ọ̀fẹ́ Fún Ẹgbẹ̀rún Márùn-ún Àwọn Ènìyàn Ni…
Awọn ọmọ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí wọn gbé ni òkè òkun, ti orúkọ ẹgbẹ náà jẹ Ọmọ Ìlú Eko, ní àwọn ti ṣetán láti ran àwọn ènìyàn ẹgbẹrun marun-un lọwọ fún ìwòsàn ọfẹ kakakiri agbègbè ìlú Eko.
Nígbà tí wọn ń sọ̀rọ̀ níbi ayẹyẹ àyájọ́ ọjọ́…
Ọ̀ọ́dúnrún (300) Àwọn Ògo Wẹẹrẹ Ni Ó Ti Ní Àrùn Jẹjẹrẹ- Àyẹ́wò Sàfihàn Ní Ilé…
Akọ́ṣẹ́mọṣẹ́, ní ilé ìwòsàn Yunifásitì, ìpínlẹ̀ Èkó, Dókítà Abidemi Omonisi ti sàlàyé pé ọ̀ọ́dúnrún àwọn ògo wẹẹrẹ ni àyẹ̀wò fi hàn pé ó ní àrun jẹjẹrẹ láàrin odún kan
Omonisi sọ ọ̀rọ̀ náà ní…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Eko Pẹ̀lú Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ Àjọ SFH Ti Gbáradì Láti Gbogunti Àìsàn Ibà
Àjọ tí ó ń mójútò ètò ìlera ìdíle (SFH) pẹ̀lú ìfọwọ́sowọ́pọ̀ àjọ elétò ìlera ìpínlẹ̀ Eko ti gbáradì láti gbógunti àìsàn Ìba ní Ìpínlẹ̀ Èkó
Àjọ SFH ń siṣẹ́ pẹ̀lú ìrànlọ́wọ́ Banki àgbáyé láti…
Akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ Pàrọwà Sí Àwọn Ọkùnrin Láti Mú Àdíkù Bá Ọtí Mímu Lójúnà Àti Dènà…
Dókítà Chidiebere Ogo ti gba àwọn Ọkùnrin tí ó ti lé ní ogójì ọdún nímọ̀ràn láti jìnà sí àpọ̀jù ọtí mímu lójúnà àti mu àdíkù bá àrùn jẹjẹrẹ
Ogo, tí ó jẹ́ oníwòsàn àgbà ní ilé ìwòsàn…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Kwara Pẹ̀lú Yunifásitì Al-Hikma Ti Ní Ìfẹnukò Fún Ìdásílẹ́ Ilé Ìwòsàn…
Lójúnà àti mú ìgbòòrò bá ètò ìlera àti ètò ẹ̀kọ́ ní ìpínlẹ̀ Kwara, ìjọba Ìpínlẹ̀ Kwara ti gbé ìgbésẹ̀ akin pẹ̀lú bíbuwọ́lu ìwé àdéhùn kan pẹ̀lú Yunifasiti Al-Hikma èyí tí yóò mú kí ìdásílẹ̀ ilé…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Eko Ní Èróngbà Látí Ṣe Ìrànlọ́wọ́ Abẹ́rẹ́ Àjẹsára Fún Àwon Ènìyàn Tó Tó Mílíọ́nù…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Eko sọ wí pé o kéré jù àwọn ènìyàn tó tó Mejidinlogun Mílíọ̀nù ni yóò gbà abẹ́rẹ́ àjẹsára láti dènà àrùn rọmọlápárọmọlẹ́sẹ̀, ètò yìí yóò wáyé ní ọjọ́ kankan dilogun oṣù mẹwàá 2024.
Dókítà Abímbólá Bowale, to jẹ akọwe fún…
Hajj Ọdún 2024: Ìpínlẹ̀ Èkó Ń Fẹ́ Àtìlẹyìn Àjọ Port Health Service Lórí Abẹ́rẹ́ Àjẹsára
Àjọ Lagos State Muslim Pilgrims Welfare Board ti pe fún ajọṣepọ pẹlu àjọ Port Health Service (PHS) fún eto abẹrẹ ajẹsara ati Ipese Káàdì alawọ omi ọsàn lai fi àsìkò sofo fún eto irinajò Umurah ti ọdún yìí.
Akọwe àjọ náà,…
Ìpínlẹ̀ Niger Mú Àtúnṣe Àti Ìdàgbàsókè Bá Àwọn Ilé Ìwòsàn Káàkiri Àwọn Ijọba Ìbílẹ̀ Náà
Nínú èròngbà láti mú ìdàgbàsókè bá ètò ìlera káàkiri ìjoba ìbílẹ̀ márùn-únlélógún tó wà ní ìpínlẹ̀ Niger.
Gómìnà ìpínlẹ̀ náà ti bẹrẹ àwọn àtúnṣe nlá sí àwọn ilé ìwòsàn to wa láwọn ìjọba ìbílẹ̀ náà fún ìdàgbàsókè tó péye.
Ìyàwó Gómìnà…
Ààrẹ Fún Ẹgbẹ́ DEPOWA Ṣí Ilé Ìgbẹ̀bí Sí Ilé Ìwòsàn NDA Ni Ìpínlẹ̀ Kaduna.
Ààrẹ fún ẹgbẹ́ ìyàwó àwọn òṣìṣẹ́ elétò ààbò àti àwọn Ọlọ́pàá DEPOWA, Ìyáàfin Ogbogbo Musa ti sí ilé igbebi fún àwọn obìnrin ní ilé ìwòsàn NDA ní Ribadu cantonment ni ìpínlẹ̀ Kaduna.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ o ní ilé igbebi náà jẹ ohun ti o tí wa…
Ènìyàn Leè, Ṣe ìtọ́jú Àìsàn Ìtọ̀ Suger Nípa Jíjẹ Oúnjẹ Tó Sara Lóore: Àwọn Onímọ̀ Nípa Oúnjẹ.
Onímọ̀ nípa oúnjẹ jíjẹ, Ìyáàfin Ifeoluwa Akinyinka, ti gba àwọn ènìyàn Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lámọ̀ràn láti rí wí pé wọn n jẹ àwọn oúnjẹ tó ṣe ará lóore lọpọ ìgbà
Ó ní ipá àwọn oúnjẹ tó ṣe ará lóore wọnyi yóò dènà àìsàn ìtọ̀ Suger àti…