Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌDÁNILÁRAYÁ
This is a category for entertainment news
Toyin Abraham Mú Orílé Orílẹ̀-èdè United Kingdom Láti Sí Sinimá Tuntun Tí Àkọlé Rẹ̀ Jẹ́…
Gbajú-gbajà eléré orí ìtàgé ọmọ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Toyin Abraham ti kéde fún gbogbo àgbáyé pé sinimá tuntun Òun yóò jáde ní Orílẹ̀-èdè United Kingdom ní ọjọ́ Ẹtì, ọjọ́ karùn-ún osù kíní ọdún 2024.…
Arábìnrin Asantewaa Ṣètò Látí Fí Ìtàn Balẹ̀ Nínú Ìwé ‘Guinness World Record’
Arábìnrin ọmọ Orílẹ̀-èdè Ghana kàn, Afua Asantewaa Aduonum tí wà lórí ìrìn-àjò láti fi orúkọ rẹ̀ sínú ìwé Àgbáyé 'Guinness World Record' fún ìdíje eré orin tó pẹ́ jùlọ.
Nínú ìgbìyànjú rẹ̀ látí fí orúkọ rẹ̀ parọ tí Sunil Waghmare ọmọ…
Ìgbẹkẹ̀lé Nínú Àwọn Ọ̀dọ́ Se Pàtàkì Fún Ìdàgbàsókè Àwùjọ- Onaiyekan Pàrọwà Sí…
Cardinal John Onaiyekan tí ó jẹ́ alàgbà ìjọ Kátólììkì ẹka ti Abuja ti rọ àwọn olósèlú láti rí ìgbẹkèlé nínú àwọn ọ̀dọ́ gẹ́gẹ́ bí okùnǹfà fún ìdàgbàsókè àwùjọ
Ó sọ ọ̀rọ̀ náà fún àwọn oníròyìn…
Gbajúgbajà Òṣèré Tíátà Lewis Tó Di Ìlú Mọọkà Nínú Eré Headmaster Tí Jáde Láyé.
Gbajúgbajà Òṣèré Tíátà tí gbogbo àwọn ènìyàn mò ninu eré Headmaster, Dejumo Lewis ti jade láyé.
Ìròyìn di mímọ láti ọ̀dọ Òṣèré Tíátà ẹgbẹ́ rẹ Saidi Balogun nínú ọ̀rọ̀ rẹ ni orí aféfé Instagram rẹ ni ọjọ́ Sátidé.
Nígbà tí o n ṣe àfihàn…
Àmójútó Àṣà Àti Ohun Ìsẹ̀ǹbáyé Yóò Mú Ìgbòòrò Bá Ọrọ̀ Ajé- Kọmísọ́nà Tẹ́lẹ̀rí
Kọmísọ́nà tẹ́lẹ̀rí Fún Ìbára-ẹni-sọ̀rọ̀ Àti Àṣà ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Ajagun fẹ̀yìntì Ibrahim Bata Malgwi Haruna ti sọ pé, Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ní ànfààní láti lo Àṣà àti àwọn Ohun ìṣẹ̀ǹbáyé rẹ̀…
Ọọni Ti Ilé Ifẹ Pàrọwà Sí Ọmọ Nàìjíríà Láti Gbé Àṣà Wa Lárugẹ
Ọọni Tí Ilé Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi ti pàrọwà sí ọmọ Nàìjíríà Láti gbé Àṣà àti ìṣe wa lárugẹ ní ilé àti lókè òkun
Ó sọ ọ̀rọ̀ náà nígbà tí ó ń se ìfilọ́lẹ̀ gbọ̀ngàn Erelu Yeye Oodua ní ọjọ́ Àìkú…
Gbajúgbajà Òsèré Orí Ìtàgé, Lateef Adedimeji Gba Àmì Ẹyẹ Fún Ipò Ọ̀mọ̀wé
Gbajúgbajà òsèré orí ìtàgé, Lateef Adedimeji ni wọ́n ti fi àmì ẹ̀yẹ dá lọ́lá sí ipò ọ̀mọ̀wé ní ẹka Àṣà àti ohun ìsẹ̀ǹbáyé ní yunifásitì Orílẹ̀-èdè Benin Republic
Òsèré náà kéde àseyọrí rẹ̀…
Ìdàgbàsókè Yóò Débá Ìgbòkè-gbodò Ọkọ̀ Òfurufú Ní Cross River- Bassey Otu
Gòmìnà Ìpínlẹ̀ Cross River, Bassey Otu ti parí ètò láti mú ìgbòòrò bá ìgbòkè-gbodò ọkọ̀ òfurufú, nígbà tí ó gba ilé iṣẹ́ Aero láyè lati bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ní ìlú Calabar
Gómìnà Otu tún gbé ìgbésẹ̀…
Iwobi Rawọ́ Ẹ̀bẹ̀ Sí Àwọn Ọmọ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Láti Ní Sùúrù.
Ọmọ ẹgbẹ́ agbaboolu Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Alex Iwobi ti rawọ ẹ̀bẹ̀ sí àwọn olólùfẹ̀ rẹ láti ní sùúrù to pọ fún àwọn,
wọn ní àwọn yóò sa gbogbo agbara awọn láti rí wí pé àwọn kópa nínú ìdílé bọọlu àgbáyé ti ọdún 2026.
Orílẹ̀-èdè…
Adarí Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Ìpínlẹ̀ Kwara Sèdárò Lẹ́yìn Ikú Gbajú-gbajà Òsèré, Samanja
Adarí Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Ìpínlẹ Kwara, Ààrin Gbìngbìn Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Onímọ̀-ẹ̀rọ Yakubu Danladi-Salihu ti sàpèjúwe ikú Alhaji Usman Baba Patigi tí gbogbo ayé mọ̀ sí Samanja gẹ́gẹ́ bí òfò ńlá sí àwùjọ…