Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌDÓKOÒWÒ
This is a category for business news
Ilé Iṣẹ́ Bua Gé Owó Sìmẹ́ǹtì Lọ Sílẹ̀ Ṣí Ẹgbẹrún Mẹ́ta Ààbọ̀ Náírà
Ile iṣẹ to n se cement -BUA ni alẹ́ àná kéde lílọ sílẹ̀ iye owó ti wọn ń ta Sìmẹ́ǹtì láti ẹgbẹ̀run màrún/mẹ́fà sí Ẹgbẹ̀rún Mẹ́ta Ààbọ̀ Náírà fún báàgì kan láti òní lọ.
Nínú akọsilẹ kan ti awọn alábójútó ilé ìṣẹ́ buwọ́lù, wọn sì gée, wọn…
Nàìjíríà Pẹ̀lú Àjọ Yúrópù Yóò Ṣé Àjọṣepọ̀ Lórí Ìlànà Ètò Ọrọ̀-àjé
Ìjọba orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ní àjọṣepọ̀ pẹ̀lú Ajọ Yúrópù (European Union, EU) tí ṣé ìdánilẹ́kọ̀ọ́ lórí ọrọ̀-ajé gẹ́gẹ́ bí ará àwọn akitiyan láti ṣé àtìlẹ́yìn ìyípadà orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lórí ètò ọrọ̀-àjé.
Èyí yóò ṣé ìrànlọ́wọ́ fún…
Ẹ́wá Ńkàn Ṣé Sí Ọrọ̀ Pàṣí pàárọ̀ Ní Kìákiá, CPPE Rọ́ Gómìnà Bànkí Àpapọ̀
Ajọ́ Centre for the Promotion of Private Enterprise (CPPE) tí rọ Gómìnà túntún tí Bànkí àpapọ́ Nàìjíríà, Olayemi Cardoso, tí wọ́n ṣẹṣẹ yàn pé kó ṣé àtúnṣé ọjá pàṣí pàárọ̀ owó ní kiakia.
Muda Yusuf, oludari ti CPPE, ṣe afihan eyi ninu…
Ìpàdé G20: Ànfààní Tó Dára Fún Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Ìjọba Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà sọ wí pé ìpàdé G20 ti yóò mú àwọn adarí Orílẹ̀-èdè káàkiri péjọ ni Orílẹ̀-èdè India jẹ ànfààní nlá fún Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Wọn ní èyí yóò fi hàn wí pé ìjọba Ààrẹ Bọla Tinubu gbà ànfààní náà láyè lai wo ẹ̀yìn,…
Mínísítà Olú-ìlú Nàìjíríà Gbèrò Látí Máà Ló Owó Tí Ilé-iṣẹ́ Náà Pá Fún Àwọn Iṣẹ́ Àkànṣe
Mínísítà tí Olúìlú Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Abuja, Nyesom Wike tí kéde pé láti àkókò yíì, àwọn owó tí wọ́n bá pá lábẹ́lé (IGR) ní wọ́n yóò máa ló fún àwọn iṣẹ́ àkànṣe kàn.
Mínísítà náà sọ làkókò tó ń ṣàlàyé àwọn ìgbésẹ̀ akin látí ṣé àtúnṣe…
Mínísítà ètò ọkọ̀ òfurufú pinnu láti lo iṣòdodo fùn ìdàgbàsókè ẹ̀ka náà
Mínísítà fun ètò ìdàgbàsókè ọkọ̀ òfurufú, Festus Keyamo ti bẹrẹ iṣẹ ni kete ti aarẹ Naijiria Bọla Tinibu bura fun wọn tan ni gbọngan igbalejo aarẹ, ni Abuja, olu ilu Naijiria.
Nigba ti o n sọrọ nile iṣẹ ijọba naa, Festus…
Ilé Ìfọwópamọ́ Àpapọ̀ Ṣe Ìrànlọ́wọ́ Owó Yiyá Fún Ilé Ìfowópamọ́ Tó Ń Ba Ní Kólé Owó Tó Lé Ní Biliọnu…
Ilé Ìfọwópamọ́ Àpapọ ti Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí ṣe ìrànlọ́wọ́ owó tó lè Biliọnu Metadinlogoji Náírà fún ilẹ Ìfowópamọ́ tó n ba ni kólé ni ọdún 2022 ni èyí tí o farahàn ní nínú àkọsílẹ̀ ilé Ìfowópamọ́.
Wọn ní yíyan owó àti di dá pàdà…
Ìjọba Nàìjíríà Yóò Sán Owó Awìn IMF $3.4bn Pàdà Ní Ọdún 2027
Ìṣéjọba Ààrẹ Bola Tinubu ní ìrètí látí sàn gbèsè owó $3.4bn tí wọ́n jẹ́ Bánkì Àgbáyé 'International Monetary Fund IMF' lásìkò ìṣéjọba rẹ̀.
Ìròyìn sọ pé Ìjọba àpapọ̀ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà n'ìrètí látí sàn àpapọ̀ gbèsè pẹ̀lú èle $3.51bn…
Nàìjíríà San Gbèsè Ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta Mílíọ̀nù Dọ́là
Ìjọba orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti san gbèsè Ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta Mílíọ̀nù Dọ́là- $500 million Eurobond tí ó jẹ ni ọjọ́ Kejìlá oṣù keje ọdún 2023 nipasẹ àjọ Debt Management Office (DMO).
Àjọ DMO sọ èyí lórí ẹ̀rọ ayélujára twitter ní ọjọ́ Ọjọ́rú.…
Ààrẹ Tinubu Gbé Ìgbésẹ̀ láti se Ìdẹ̀kùn Fún Mùtú-mùwà Látàŕi Yíyọ Ìrànwọ́ Orí…
Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu ti kọ̀wé sí ilé ìgbìmọ̀ asòfin fún àtúnṣe lórí àfikún ètò ìsúná ti ọdun 2022
Adarí ilé ìgbìmọ̀ asòfin, Ọnọrébù Tajudeen Abbas ni ó ka ìwé náà nígbà tí ìjókòó àwọn…