Browsing Category
ÌRÒYÌN ÒSÈLÚ
This is a category for politics news
Kalu Kẹ́dùn Pẹ̀lú Àwọn Tí Ó Fi Ara Káásá Níbi Ìjàm̀bá Ọkọ̀ Epo Tí Ó Bú Gbàmù
Igbákejì Adarí Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Ọ̀gbẹ́ni Benjamin Okezie Kalu ti fi àìdùnnú ọkàn hàn lórí ìsẹ̀lẹ̀ láabi èyí tí ó wáyé látàrí bí ọkọ̀ epo se subú tí ó sì gbiná lẹ́ṣẹ̀-kẹṣẹ̀, èyí tí ó mú kí ọ̀pọ̀…
Ètò Ààbò Ni Ìpínlẹ̀ Oyo: Ilé Ìgbìmọ̀ aṣòfin Ìpínlẹ̀ Oyo Pọn dandan Nomba Ọkọ.
Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Ìpínlẹ̀ Oyo ti ṣe ofin wí pé ó Pon dandan fún gbogbo ọkọ́ láti ni nọmba ìdánimọ̀.
Wọn ní èyí yóò ṣe ìrànlọ́wọ́ fún ètò ààbò ni ìpínlẹ̀ náà.
Òfin yìí ni Ọ́nárébù R.A Mabaje láti ( Idọ), Ọ́nárébù Adebo Ogundoyin láti…
Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Èkó Pé Gómìnà Sanwo-Olu Láti Fọwọ́ Ọ̀kúnkúndùn Mú Ọ̀rọ̀ Àwọn Ajínri Àti…
Pẹ̀lú ìgbésẹ̀ láti fi dáàbò bo àwọn nǹkan ìní ìjọba àti ààbò àwọn ará ìlú lójú pópó, Ilé Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Èkó ti rọ Gómìnà Sanwo-Olu láti pàṣẹ fífi ọwọ́ ṣìnkún òfin mú àwọn olè akólè lójú pópó tí kò bá òfin mu.
Ilé Aṣòfin náà…
Olùdarí Ilé Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Èkó Ṣe Ìlérí Títẹ̀lé Ìlànà Ìṣàkóso Rere Àti Òdodo
Olùdarí Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Èkó, Aṣòfin Mojisola Meranda fi múlẹ̀ ní ọjọ́ Ẹtì, (Friday) tí í ṣe ọjọ́ àkọ́kọ́, tí yóò dárí Ìgbìmọ̀ Aṣòfin náà gẹ́gẹ́ bí Olùdarí Ilé náà lẹ́yìn tí wọ́n ti yọ, olùdarí àná, pé òun yóò ṣe ìjọba…
Aṣojú Sòfin Kẹ́dùn Ikú Ìyáàfin Oríyọmí Onanuga
Ilé ìgbìmọ̀ Aṣojú Sòfin ti kéde ikú Ìyáàfin Adewunmi Oriyomi Onanuga tó jẹ́ igbákejì Àgbà ilé ìgbìmọ̀ tó ń sójú fún Ikenne/Sagamu/Ariwa Remo Kòńsítúnsì Àpapọ̀ ìpínlẹ̀ Ògùn - Deputy Chief Whip of the House, representing the…
Gómìnà Gbósùbà Fún Sẹ́nétọ̀ Nwebonyi Látàrí Síṣe Ìrànlọ́wọ́ Fún Àwọn Ènìyàn…
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ebonyi, Ọ̀gbẹ́ni Francis Nwifuru ti sàpèjúwe Sẹ́nétọ̀ Onyekachi Nwebonyi gẹ́gẹ́ bi adarí rere tí ó nífẹ̀ẹ́ àwọn ènìyàn rẹ̀ atipe o jẹ ohun àmúyangàn fún ìpínlẹ̀ Ebonyi
Gómìnà sàpèjúwe ìgbésẹ̀…
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Katsina Mú Àtúntò Bá Àwọn Abẹ́sinkáwọ́ Ìjọba
Gómìnà ìpínlẹ Katsina, Mallam Dikko Umaru Radda ti buwólu àtúntò àwọn alábàásisẹ́pọ̀ ìjọba pẹ̀lú èròńgbà láti mú ìdàgbàsókè bá ìpínlẹ̀ náà
Nínú ìfọ̀rọ̀léde láti ọwọ́ olùfọ̀rọ̀léde sí gomina,…
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Borno Darí Ìpàdé Àpérò, Ó Buwọ́lu Síṣe Àkànse Iṣẹ́
Gómìnà Babagana Umara Zulum darí ìpàdé àpérò àkọ́kọ́ fún ọdún 2025 níbi tí ó ti sàgbéyẹ̀wò àwọn àseyorí tí ó wáyé ní ọdún 2024, Ó sì buwọ́lu àwọn iṣẹ́ àkànse tí wọn yóò dáwọ́lé
Níbi…
Oloro Ti Oro Tuntun Gorí Ìtẹ́ Lẹ́yìn Ẹ̀tàlélógòjìlénígba Ọdún Tí Ìran wọn Ti Jẹ
Ọjó málegbàgbé àti ọjọ́ ayọ̀ ló jẹ́ ni ilú Oro nígbà ti Oba alayeluwa tuntun, Joel Olaniyi Oyatoye Titiloye Olufayo II gorí ìtẹ́ àwọn bàbá rẹ pẹlú adé lori.
Èyí wáyé lẹ́yìn Ẹ̀tàlélógòjìlénígba Ọdún ti Iran wọn ti je gbẹ̀yìn.…
Àwọn lọ́balọ́ba ìpinlẹ̀ Ọ̀ṣun gbóríyìn fún Aṣòfin Bamidele Salam
Àwọn lọ́balọ́ba tó ju ọgọ́rùn ún lọ láti ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́rin ní Àríwá Ẹdẹ, Gusu Ẹdẹ, Egbedore, àti agbègbè ìjọba àpapọ̀ Èjìgbò ti ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun ti gbóríyìn fún Ọ̀gbẹ́ni Bamidele Salam.
Wọ́n rí ipa pàtàkì tó…