Browsing Category
ÌRÒYÌN ÒSÈLÚ
This is a category for politics news
Ẹ Fi Àdúrà Jagun Fún Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Lásìkò Ààwẹ̀ Ramadani- Adarí Ilé Asòfin…
Adarí Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin, Ọ̀gbẹ́ni Abbas Tajudeen ti pàrọwà sí àwọn Mùsùlùmí ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà láti gbàdúrà fún Orílẹ̀-èdè àti àwọn adarí, bí ààwẹ̀ Ramadani se gbérasọ
Abbas sàfirinlẹ̀…
Aṣáájú Nàìjíríà Jẹ́jẹ̀ẹ́ Láti Sápá Òun Síi Lórí Ààbò Oúnjẹ
Ààrẹ Nàìjíríà, Bola Ahmed Tinubu tí ṣé ìlérí láti túbọ̀ sápá òun sí lórí àṣeyọrí oúnjẹ, ìdókòwò àti ìdàgbàsókè jákèjádò orílẹ̀-èdè náà.
O ṣé ìlérí náà ní Abuja, Olú-ìlú Orílẹ-èdè l'àkókò tí gbogbo àwọn ọmọ 'All Progressive Congress…
Ààrẹ Tinubu Ṣèlérí Láti Dúró Fún Ètò Ọrọ-Àjé Tó Dára Fún Nàìjíríà
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu tí ṣèlérí láti ṣé ìtọ́jú ètò ọrọ-àjé Nàìjíríà, èyítí yóò ṣé adínkù nínú owó oúnjẹ, pàápàá júlọ l'àkókò àwẹ Ramadan yìí.
Ààrẹ Tinubu sọ èyí lásìkò tó n sọrọ níbí ìpàdé Ìgbìmọ̀ Aláṣẹ tí ẹgbẹ́ òṣèlú tí 'All…
Ààrẹ Tinubu Kí Gómìnà Asẹ̀sẹ̀dìbòyàn Ìpínlẹ̀ Ondo Kú Oríire
Ààrẹ Tinubu ti ki Lucky Orimisan Aiyedatiwa kú oriire bi wọ́n ti ṣe se ìbúra fún si ipò Gómìnà tuntun ìpínlẹ̀ Ondo pé kó tẹ̀lé àwòkọ́ṣe rere asíwájú rẹ̀.
Ààrẹ gba Aiyedatiwa nímọ̀ràn kí ó lo ijọba rẹ̀ láti sìn àwọn ènìyàn rẹ̀,…
Ẹ Máṣe Di Ìbò Ìjọba Ìbílẹ̀, Alága Gba Ìjọba Nímọ̀ràn
Alága ẹgbẹ́ -Association of Local Governments of Nigeria (ALGON) ti pàṣẹ láti má jẹ ki gbogbo àpò ìkówósí gbogbo ìgbìmọ̀ kó ṣiṣẹ́ mọ́ ní wàrànsesà bí ó ti ń bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ní ọjọ́ Ọjọ́rú lẹ́yìn tí wọ́n dá Alága ìjọba àti àwọn…
Ara Ìpínlẹ̀ Cross River Ni Bakasi Wà- Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Ìpínlẹ Cross River Sọ̀rọ̀ Sókè
Àwọn Ọmọ Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Cros River ti bu ẹnu àtẹ́ lu ìpè kan tí ó wáyé, èyí tí ó pè fún pípa orúkọ ìjọba ìbílẹ̀ Bakasi rẹ́ kúrò ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà
Àwọn ọmọ asòfin náà pàrọwà sí àwọn…
Ilé Aṣòfin Èkó Sẹ́ Awuyewuye Pé, Aya Ààrẹ, Aṣòfin Olúrẹ̀mí Tínubu Mọ̀ Sí Aáwọ̀ Tó Ń Wáyé Nínú Ilé…
Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Èkó ti ṣẹ́ awuyewuye pé, Aya Ààrẹ, Aṣòfin Olúrẹ̀mí Tínubu ló wà nídìí ááwọ̀ tó ń wáyé nínú Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin náà.
Àtẹ̀jáde náà ní Alága Ètò Ìròyìn, Alukoro àti Ètò Ààbò ìlú, nínú Ilé Aṣòfin náà,…
Erin Wó, Àjànàkú Sùn Bí Òkè, Edwin Clark Dágbére Fáyé, Adarí Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin…
Adarí Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin, Ọ̀gbẹ́ni Abbas Tajudeen àti igbákejì rẹ̀ Benjamin Kalu ti sèdárò lẹ́yìn olóògbé, olóyè Edwin Kiagbodo Clark, wọ́n sàpèjúwe rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí asíwájú rere tí ó fi gbogbo ara jì fún…
Ilé Aṣòfin Èkó Se Atìlẹ́yìn Fún Olùdarí Ilé Aṣòfin Náà, Aṣòfin Meranda.
Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Èkó fi ìgbẹ́kẹ̀lé àti àtìlẹ́yìn wọn hàn sí Olùdarí Ilé Aṣòfin náà, Aṣòfin Mojísọ́lá Meranda lẹ́yìn àhesọ̀ ọ̀rọ̀ tó ń lọ ní ìgboro pé, ó ti kọ̀wé fi ipò sílẹ̀.
Aṣòfin Ọladipọ Ajọ̀màle tó ń ṣojú ẹkùn…
Sẹ́nétọ̀ Nwebonyi fún àwọn aláìní ní ẹ̀bùn ilé ní ìpínlẹ̀ Ebonyi
Igbákejì ọ̀gá àgbà whip ilé ìgbìmọ̀ Aṣojú ti Nàìjíríà, Sẹnetọ Onyekachi Nwebonyi ti ṣe àgbékalẹ̀ ilégbèé aládàákọ́ méjì, oní yàrá méjì àti kànga ìgbàlódé sí agbègbè rẹ̀.
Iyawo Gomina ipinlẹ Ebonyi,…