Take a fresh look at your lifestyle.
Browsing Category

ÌRÒYÌN ÒSÈLÚ

This is a category for politics news

Àṣeparí ìdìbò gómìnà : Alága INEC rọ àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìdìbò láti ṣe iṣẹ́ wọn…

Alága ìgbìmọ̀ olómìnira tó ń mójútó ètò ìdìbò lórílẹ̀-èdè, INEC, Ọ̀jọ̀gbọ́n Mahmood Yakubu ri rọ àwọn òṣìṣẹ́ ìgbìmọ̀ náà láti ṣàfihàn bí wọ́n ṣe nífẹ̀ẹ́ orílẹ̀-èdè wọn àti ìmọṣẹ́ wọn bíi iṣẹ́. O pe…

Ọ̀gá Àgbà Àpapọ̀ Fún Àjọ Ọlọ́pàá Ti Pàṣẹ Ìsípòpadà Kọmísọ́nà Àjọ Náà Ní Ìpínlẹ̀…

Ọgá Àgbà Àpapọ̀ Àjọ Ọlọ́pàá, Kayọde Ẹgbẹtokun ti pàṣẹ ìsípòpadà alákòóso àjọ náà ní ìpínlẹ Imo, Ọgbẹni Mohammed Barde sí ọ́ọ́fìsì àpapọ̀ àjọ náà ní ìlu Abuja. Ọ̀rọ̀ náà wáyé nínú ìfiléde…

Rògbòdìyàn ìpínlẹ̀ Rivers: Gómìnà Fubara dúpẹ́ lọ́wọ́ ààrẹ Tinubu fún dídásí rẹ̀

Gómìnà ìpínlẹ̀ Rivers, Siminalayi Fubara ti fi ọpẹ́ rẹ̀ hàn sí ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu fún “ìdásí àgbà” nínú rògbòdìyàn olóṣèlú tó wáyé ní ìpínlẹ̀ náà láìpẹ́ yìí. Ninu alaye kan ti funra rẹ buwọlu ti o…

Ìkọlù Ẹgbẹ́ Òṣìṣẹ́ Ní Ìpínlẹ̀ Imo: Gbajugbaja Nínú Ẹgbẹ́ Òṣèlú NNPP Ke Sì Àwọn Agbófinró Láti Fi Ojú…

Gbajúgbajà nínú ẹgbẹ́ òṣèlú NNPP tó tún jẹ́ bàbá isalẹ fún ẹgbẹ́ Akọ̀ròyìn ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ (Oyo State Correspondents' Chapel) Olufemi Ajadi Oguntoyinbo tí korò ojú sí ìkọlù sí Ààrẹ ẹgbẹ́ oṣiṣẹ Joe Ajero lásìkò tí òun àti ẹgbẹ́ oṣiṣẹ ni…
button