Take a fresh look at your lifestyle.
Browsing Category

ÌRÒYÌN ORÍLẸ̀-ÈDÈ NÀÍJIRÍÀ

This is a Nigeria news category

NELFUND pín iye owó tó lé ní Bílíọ́nù mẹ́rìndínlọ́gọ́ta Náírà fún ẹ̀yáwó akẹ́kọ̀ọ́

Àjọ tí ń rísí owó yíyá fún ẹ̀kọ́ ní Nàìjíríà (NELFUND), ti kéde pínpín iye owó tó lé ní Bílíọ́nù mẹ́rìndínlọ́gọ́ta Náírà láìgba èlé fún àwọn ilé ẹ̀kọ́ gíga tíjọba jákèjádò orílẹ̀-èdè láti bí…

Àṣeyọrí Àtúnṣe Ètò-ọrọ Àjé Ní Kí Ilé-iṣẹ́ NNPCL Gúnlè Fún Ìtẹ̀síwájú – Ààrẹ Nàìjíríà

Ààrẹ Bola Tinubu tí gbá àwọn ìgbìmọ̀ túntún fún ilé-ìfọpo Nàìjíríà (Nigerian National Petroleum Company Limited NNPCL) tó ṣé ìfilọ́lẹ̀ rẹ̀ gúnlè ìlọsíwájú tó ṣé nípasẹ àwọn àtúnṣe ètò-ọrọ àjé, èyítí o fí gbóríyìn fún Imúdára àti ìpèsè ayé…

Ó Lé Ní Ẹgbẹ̀rún Mẹ́talá Àwọn Oníjágìdíjagán Tí Á Tí Dá Lọ́wọ́ Kọ́ Láàrín Oṣù Kàrún 2023 Sí Ọdún Yìí…

Olùdámọ̀ràn Ààbò tí Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà (NSA), Mallam Nuhu Ribadu, tí sàlàyé pé ó lé díẹ̀ ní ẹgbẹ̀rún mẹ́talá àbọ̀ (13,543) àwọn oníjágìdíjagán àti àwọn afurasi ọdaràn mìíràn ní a tí dá lọwọ́ kọ́ yọ́ kúrò ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà láti oṣù…

Ààrẹ Tinubu Ṣàfihàn Ìlọsíwájú Ẹgbẹ́ APC Sí Àwọn Àtúnṣe Ètò Ọrọ-àjé ‎

Ààrẹ Bola Tinubu tí sọ pé àtìlẹ́yìn tó ń pọ̀ sí i fún ẹgbẹ́ òṣèlú 'All Progressives Congress' (APC) ló jẹ́ àṣeyọrí àgbàyanu tí ẹgbẹ́ náà ṣe láàárín ọdún méjì àkọ́kọ́ tí wọ́n ti lò lẹ́nu iṣẹ́ ìjọba, ó sì fi dá àwọn ọmọ Nàìjíríà lójú pé…

Ètò Ẹ̀kọ́: Ìyàwó Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Rẹmi Tinubu Bèrè Anfààní Ẹ̀kọ́ Ọfẹ Fún Àwọn Ọ̀dọ́.

Ìyàwó Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Oluremi Tinubu, sọ wí pé oun ṣiṣe lórí bí ètò ẹ̀kọ́ ọfẹ yóò ṣẹ wa fun àwọn ọ̀dọ́ Nígbà tí o ń ba aláṣẹ ilé iṣé MERCK Foundation sọ̀rọ̀, ilé iṣé ti o jẹ aláàdáni láti Orílẹ̀-èdè German nígbà tí wọn ṣe àbẹ̀wò…
button